Jàjá ìlú Òpobò

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Jàjá ìlú Òpobò
Jaja of Opobo
Amanyanabo
[[File:|frameless|alt=]]
Jàjá ìlú Òpobò, Opobo
Orí-ìtẹ́25 December 1870–September 1887
Orí-oyè25 December 1870
OrúkọJubo Jubogha "Jaja"
LanguageIgbo
Ọjọ́ìbíc. 1821
IbíbíbísíOrlu[citation needed]
Aláìsíc. 1891
ÌsìnkúOpobo
AṣájúNone
Arọ́pọ̀Perekule
ẸbíajọbaJaja
BàbáOzurumba
ÌyáUru

Jaja ilu Opobo

Ọba Jaja tí ìlú Opobo (Orúkọ:  Jubo Jubogha, 1821 - 1891) jẹ́ ọmọba oníṣòwò, òun sì ní olùdásílẹ̀ ìlú Opobo, tí ó wà ní ìlú Ìpínlẹ̀ Rivers tí ìlú Nàìjíríà. Wọ́n bí ni Umuduruoha Amaigbo ní ìpínlẹ̀ Imo, ọ̀dọ̀ ló wà nígbà tí àwọn afẹ́rú-ṣòwò mú lẹ́rú ní Bonny. Orúkọ tó padà jẹ́ ni "Jájá"

Jaja of Opobo: Ní ọdún 1792, Jaja of Opobo di Ọba Banny. Ó kú ní 1829.

Mohammed Bello[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Mohammed Bello: Mohammed Bello tí ó jẹ́ ọmọ Uthman dan fodio kọ́ ìlú Sokoto ní 1809. Ní 1817 nígbà tí baba rẹ̀ kú, ó di Caliph ibẹ̀.

Shodeke[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Shódẹkẹ́: Ní 1825, Shódẹkẹ́ di aṣáájú àwọn Ẹ̀gbá ní Abẹ́òkúta.

Baale Ibadan[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Baálẹ̀ Ìbàdàn: Ní ọdún 1830, wọ́n dá Ìbàdàn sílẹ̀ ó sì ní Baálẹ̀ àkọ́kọ́