Kabiru Idris
Ìrísí
Kabiru Idris jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. O sìn gẹ́gẹ́bíi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè ẹkùn ìdìbò Kura/Madobi/Garun Malam ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà. Wọn bí ní ọdún 1973, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Kano. Wọn dibo yàn sì ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà nínú ètò ìdìbò gbogbo gbo ọdún 2019 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC).[1][2]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-07.
- ↑ vanguard (2019-02-25). "APC wins 19 out of 24 federal constituencies in Kano". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-07.