Jump to content

Kayode Opeifa

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Kayode Opeifa
Managing Director of the Nigeria Railway Corporation
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
22 January 2025
ÀàrẹBola Tinubu
AsíwájúEngr. Fidet Okhiria
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí21 Oṣù Kàrún 1965 (1965-05-21) (ọmọ ọdún 60)
Alma materUniversity of Ilorin
OccupationTransport expert, Politician

Isiak Káyọ̀dé Ọpẹ́ifá (tí wọ́n bí 21 oṣù May, ọdún 1965) jẹ́ onímọ̀ ètò ìrìnnà ọkọ̀ àti olùkọ́ ifáfitì ọmọ Nigeria tí ó jẹ́ ọ̀gá-àgbà ilé-iṣẹ́ ọkọ̀ ojúurin, Nigerian Railway Corporation (NRC), lẹ́yìn tí Ààrẹ Bọlá Tinubu yàn án lọ́jọ́ 22 oṣù odun 2025. Ó ti fì'gbà kan jẹ́ Kọmíṣánnà fún ètò ìrìnnà ọkọ̀ tí Ìpínlẹ̀ Èkó nígbà ìjọba Babatunde Fashola.[1][2][3][4]

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "'WHAT LIFE HAS TAUGHT ME AT 49' -KAYODE OPEIFA, Lagos Commissioner for Transport". Encomium (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2014-06-02. Retrieved 2025-01-22.
  2. Ogunseyin, Oluyemi (2025-01-22). "Tinubu appoints Opeifa as NRC MD". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-22.
  3. Oduah, Henry (2025-01-22). "Tinubu appoints former Lagos transport commissioner, Kayode Opeifa, as NRC MD". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-22.
  4. Omidiji, Rachael (2025-01-22). "Tinubu appoints Opeifa as MD, Nigeria railway corporation". Tribune Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-22.