Kayode Opeifa
Ìrísí
Kayode Opeifa | |
|---|---|
| Managing Director of the Nigeria Railway Corporation | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
| Ó gun orí àga 22 January 2025 | |
| Ààrẹ | Bola Tinubu |
| Asíwájú | Engr. Fidet Okhiria |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 21 Oṣù Kàrún 1965 |
| Alma mater | University of Ilorin |
| Occupation | Transport expert, Politician |
Isiak Káyọ̀dé Ọpẹ́ifá (tí wọ́n bí 21 oṣù May, ọdún 1965) jẹ́ onímọ̀ ètò ìrìnnà ọkọ̀ àti olùkọ́ ifáfitì ọmọ Nigeria tí ó jẹ́ ọ̀gá-àgbà ilé-iṣẹ́ ọkọ̀ ojúurin, Nigerian Railway Corporation (NRC), lẹ́yìn tí Ààrẹ Bọlá Tinubu yàn án lọ́jọ́ 22 oṣù odun 2025. Ó ti fì'gbà kan jẹ́ Kọmíṣánnà fún ètò ìrìnnà ọkọ̀ tí Ìpínlẹ̀ Èkó nígbà ìjọba Babatunde Fashola.[1][2][3][4]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "'WHAT LIFE HAS TAUGHT ME AT 49' -KAYODE OPEIFA, Lagos Commissioner for Transport". Encomium (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2014-06-02. Retrieved 2025-01-22.
- ↑ Ogunseyin, Oluyemi (2025-01-22). "Tinubu appoints Opeifa as NRC MD". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-22.
- ↑ Oduah, Henry (2025-01-22). "Tinubu appoints former Lagos transport commissioner, Kayode Opeifa, as NRC MD". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-22.
- ↑ Omidiji, Rachael (2025-01-22). "Tinubu appoints Opeifa as MD, Nigeria railway corporation". Tribune Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-22.