Kehinde Agboola
Ìrísí
Kehinde Agboola jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. O sìn gẹ́gẹ́bíi ọmọ ilẹ̀ igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú ẹkùn idibo Ikole/Oye ni ilé igbimọ aṣòfin. O jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Ekiti State. Won dibo yàn sì ilé igbimọ aṣòfin àgbà ni ọdún 2015 nínú ètò ìdìbò gbogbogbo lábé ẹgbẹ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP).[1][2]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-08.
- ↑ "Hon. Kehinde Agboola biography, net worth, age, family, contact & picture". www.manpower.com.ng. Retrieved 2025-01-08.