Kehinde Sofola
| Kehinde Sofola |
|---|
Oloye Kehinde Sofola, QC, SAN, MON, CON (ọjọ kẹwàá oṣù kẹta ọdún 1924 – ọjọ kẹẹ́dogun oṣù kẹta ọdún 2007) [1] jẹ gbajugbaja onidajọ àti Minisita fun ètò Idajọ ni ìṣèjọba Kejì Naijiria . [2]
Ìbẹ̀rẹ̀ Ìgbésí ayé àti iṣẹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Olóyè Sofola ni a bi ni ọjọ kẹwàá Oṣu Kẹta, Ọdún 1924, gẹgẹ bi ọkan nínú àwọn ipele keji àwọn Ìbejì mẹta ni ipinlẹ Ogun, gúúsù ìwọ̀-oòrùn Nàìjíríà. [3] Wọ́n pè é sí ọgbà Gẹ̀ẹ́sì ní ọjọ́ kọkànlá oṣù kẹsàn-án ọdún 1954. [4] Ó jẹ́ Olùdásílẹ̀ ọgbà Kehinde Sofola, ilé iṣẹ́ amòfin kàn ní ìpínlẹ̀ Èkó níbi tí Ayotunde Phillips tó jẹ́ Adajọ́ àgbà ní ìpínlẹ̀ Èkó ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ ní oṣù kẹsàn-án ọdún 1976. [5] [6] Ó di Agbẹjọ́rò àgbà lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní ọdún 1978.[3]
Ìgbésí ayé ará ẹni
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ẹ̀gbọ́n l'ọkunrin loje fun Idowu Sofola, Alaga ẹgbẹ́ Benchers Naijiria . Ọmọ rẹ akọbi Kayode Sofola jẹ Agbẹjọro Àgbà ti Naijiria ati Alága ti United Bank for Africa tẹlẹ rí. [7] [8]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2018-03-24. Retrieved 2025-08-14.
- ↑ https://books.google.com/books?id=HULYAAAAQBAJ&q=Justice+Kehinde+Sofola&pg=PA164
- 1 2 https://www.pressreader.com/nigeria/thisday/20170321/281715499436641
- ↑ .https://books.google.com/books?id=O6Eiaw0oYRYC&q=Justice+Kehinde+Sofola&pg=PA129
- ↑ https://web.archive.org/web/20150514111130/http://newtelegraphonline.com/lagos-cj-historic-succession-of-two-sisters/
- ↑ https://web.archive.org/web/20120826051756/http://www.punchng.com/feature/the-law-you/and-philips-steps-in/
- ↑ https://web.archive.org/web/20150725155112/http://www.thenationonlineng.net/archive2/tblnews_Detail.php?id=15109
- ↑ http://www.vanguardngr.com/2010/11/every-nigerian-woman-is-a-designer-%E2%80%94-kayode-sofolasan/