Jump to content

Kehinde Sofola

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Kehinde Sofola

Oloye Kehinde Sofola, QC, SAN, MON, CON (ọjọ kẹwàá oṣù kẹta ọdún 1924 – ọjọ kẹẹ́dogun oṣù kẹta ọdún 2007) [1] jẹ gbajugbaja onidajọ àti Minisita fun ètò Idajọ ni ìṣèjọba Kejì Naijiria . [2]

Ìbẹ̀rẹ̀ Ìgbésí ayé àti iṣẹ

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Olóyè Sofola ni a bi ni ọjọ kẹwàá Oṣu Kẹta, Ọdún 1924, gẹgẹ bi ọkan nínú àwọn ipele keji àwọn Ìbejì mẹta ni ipinlẹ Ogun, gúúsù ìwọ̀-oòrùn Nàìjíríà. [3] Wọ́n pè é sí ọgbà Gẹ̀ẹ́sì ní ọjọ́ kọkànlá oṣù kẹsàn-án ọdún 1954. [4] Ó jẹ́ Olùdásílẹ̀ ọgbà Kehinde Sofola, ilé iṣẹ́ amòfin kàn ní ìpínlẹ̀ Èkó níbi tí Ayotunde Phillips tó jẹ́ Adajọ́ àgbà ní ìpínlẹ̀ Èkó ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ ní oṣù kẹsàn-án ọdún 1976. [5] [6] Ó di Agbẹjọ́rò àgbà lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní ọdún 1978.[3]

Ìgbésí ayé ará ẹni

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ẹ̀gbọ́n l'ọkunrin loje fun Idowu Sofola, Alaga ẹgbẹ́ Benchers Naijiria . Ọmọ rẹ akọbi Kayode Sofola jẹ Agbẹjọro Àgbà ti Naijiria ati Alága ti United Bank for Africa tẹlẹ rí. [7] [8]