Keji Yusuf
Ìrísí
Keji Yusuf tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Aǹtí Kéjì (tí wọ́n bí ní September 29, 1957) jẹ́ òṣèré sinimá àgbéléwò ọmọ Nigeria[1] Ó bẹ̀rẹ̀ eré ṣíṣe nínú àwọn eré àgbéléwò orí tẹlifíṣàn tí àkọlé rẹ̀ ń jẹ́ The Child pẹ̀lú ìtọ́sọ́nà Ọ̀gbẹ́ni Lai Ashadele. [2]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Nation, The (2013-06-22). "I dare not mess up; my husband is an army officer—Nollywood actress Keji Yusuf". The Nation Newspaper. Retrieved 2025-11-01.
- ↑ Bakare, Bukola (2010-08-27). "‘I’m married, so, nobody embarrasses me’ -Keji Yusuf". Modern Ghana. Retrieved 2025-11-01.