Jump to content

Laila Johnson-Salami

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Laila Mohammed-Salami)
Laila Johnson-Salami
Laila Johnson-Salami
Ọjọ́ìbí3 December 1996
Ibadan, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ẹ̀kọ́University of Westminster
Iṣẹ́Journalist
EmployerArise News

[1]Laila Johnson-Salami (ti a bi ni ọjọ kẹta, oṣù Kejìlá, ọdún 1996) . Arabinrin Laila tí ṣiṣe pẹlu Spice TV, Nigeria Info FM, Wazobia Max TV, o si n ṣiṣẹ akọroyin lọwọ lọwọ ni ilẹ iṣẹ Arise News. Ni ọdún 2022, o gba Ẹ̀bùn ẹ̀yẹ apapọ agbaye ni ọjọ apapọ obinrin ni agbaye (UNDP/UN Women International Women’s Day Award for Media and Entertainment category)[2] wọn sì yan an fún ayẹyẹ idaniloju fún oniroyin awon eniyan ni ilẹ Afrika (Gatefield People’s Journalist for Africa Award) .[3] A mọ fún iṣẹ takuntakun ti o ṣe nípa igbesoke imudọgba abo, imulo-agbara fún àwọn ọdọ, igbesẹ lori ayipàda ojú ọjọ àti ibagbepo ninu awujọ. Arabinrin Laila ni alabarin oludasile igbimọ "We Rise Initiative", àjọ ti ko wa èrè ti a gbekalẹ fún ìdásílẹ̀ àwọn obìnrin, òun sì ni Ẹgbẹ oludasilẹ igbimo Feminist Coalition.[4][5]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Laila sí ìlú Ibadan, ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, sínú ìdílé Abayomi Salami (bàbá rẹ̀) àti Diana Yeside Johnson (ìyá rẹ̀).[6] Bàbá-bàbá rẹ̀, ìyẹn Lekan Salami jẹ́ olóyè, oníṣòwò, olóṣèlú àti olùdarí ètò eré-ìdárayá, bẹ́ẹ̀ sì ní àǹtí rẹ̀, ìyẹn Caroline Lee Johnson jẹ́ òṣèrẹ́bìnrin ní ìlú Britain.[7] Laila dàgbà sí ìlú Nàìjíríà àti UK, níbi tí ó ti gbètò ẹ̀kọ́ rẹ̀, tó sì ti gba oyè B. Sc. nínú ìmọ̀ Politics and International Relations ní University of Westminster.[8]

Ni odun 2016, o wá ni ara awọn ti wọn dá igbimọ "We Rise Initiative" ilẹ, àjọ ti ki ṣe ti ìjọba ti wọn dá sílẹ fún òmìnira àwọn obìnrin.[9][10] Arabinrin Laila pada sí ilẹ́ Nàìjíríà lati ilẹ́ òkèèrè - UK ni ọdún 2017. Ni oṣù kaarun ọdún 2018, Arabinrin Laila se ẹlẹgbẹ olukori fún ètò ti ko waye iru re ri, On the Couch with Falz and Laila, ni bi ti o ti a ayẹwo ọrọ fún àwọn tí wọn n lọ fún ipò ni eto.[11][12][13] Ni oṣù kaarun ọdún 2019, Laila darapọ mọ Arise News gegebi alabarin olukori fún ètò akọkọ ayelujara to pọ jù lọ -The Morning Show. O tun tẹsiwaju lati je alabarin ètò ọsán-News Day. Lati odun 2021 ni Laila ti ni ṣiṣe gegebi a field correspondent ni ilẹ iṣẹ Arise News ti n kọroyin nipa ayika Healthcare and international affairs. In 2021, Laila produced and presented a wildlife conservation series on Arise News in partnership with international NGO WildAid called Go Wild – a pioneer wildlife series in Nigerian media.[14] Ni ọdún 2022, Awọn àjọ ìgbìmọ̀" UNDP/UN Women International Women’s Day Award" ṣe àpèjúwe rẹ gegebi eni tí o ti ni se aseyori ninu ìmọ ẹrọ iroyin ati oniroyin ti o si n mu ayipada ba oro lori imudogba abo, imulo-agbara fún àwọn ọdọ, igbese lori ayipàda ojú ọjọ àti ibagbepo ninu awujọ, ọrọ kan nigba kan.

Àwọn àmì-ẹ̀yẹ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Arábìnrin Laila wa nínú ẹgbẹ oludasilẹ igbimọ "Feminist Coalition", ajọ tí o gbaruku ti imudọgba awọn obìnrin Nàìjíríà.

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Changing the narrative one conversation at a time.". lailajs.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-02-26.
  2. "Arise TV’s Laila Johnson-Salami Wins Int’l Award – THISDAYLIVE". www.thisdaylive.com. Retrieved 2022-07-22.
  3. "Gatefield’s People Journalism Prize for Africa 2021 Nominees". Gatefield (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-02-06. Retrieved 2022-07-22.
  4. "Nigeria's Women Are a Powerful Collective. How Are They Changing History?". Global Citizen (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-07-22.
  5. Maclean, Ruth (2021-03-12). "In Nigeria, ‘Feminist’ Was a Common Insult. Then Came the Feminist Coalition." (in en-US). The New York Times. ISSN 0362-4331. https://www.nytimes.com/2021/03/12/world/africa/nigeria-feminist-coalition.html.
  6. "LAILA JOHNSON SALAMI: My mum was the first feminist I ever knew". The Nation Newspaper (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-05-18. Retrieved 2021-12-01.
  7. Coker, Mide (2018-09-17). "Laila! Laila! Laila! – On Politics, Media and the Future of Nigeria". The Culture Custodian (Est. 2014.) (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-12-01.
  8. "‘A woman alone has power but collectively women have an impact’". Businessday NG (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-09-05. Retrieved 2021-12-01.
  9. "Rising against Sexual Violence – THISDAYLIVE". www.thisdaylive.com. Retrieved 2022-07-22.
  10. "LAILA JOHNSON SALAMI: My mum was the first feminist I ever knew". The Nation Newspaper (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-05-18. Retrieved 2021-12-01.
  11. "Watch Presidential aspirant Mr Olasubomi Okeowo Controversial Interview With Falz And Leila". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-08-20. Retrieved 2022-07-22.
  12. "Presidential aspirant wey yab Nigerians don withdraw". BBC News Pidgin. https://www.bbc.com/pidgin/tori-45244534.
  13. AfricanGlitz. "Yele Sowore, Nigeria 2019 Presidential Aspirant sits “On the Couch with Falz & Laila” to discuss Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2022-07-22. Retrieved 2022-07-22.
  14. "How Nigerian Laila Johnson-Salami has built a media career on what matters – About Her Culture" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-07-22.
  15. "ARISE TV’s Johnson-Salami Defeats Mo Abudu, Others to Win International Women’s Day Award". March 7, 2022. https://www.arise.tv/arise-tvs-johnson-salami-defeats-mo-abudu-others-to-win-international-womens-day-award/.
  16. Ugwu, Chidi (6 February 2022). "Gatefield Unveils 2021 Nominees People Journalism Prize For Africa". Independent. https://independent.ng/gatefield-unveils-2021-nominees-people-journalism-prize-for-africa/.
  17. "Seven journalists nominated for Future Awards Africa". Media Career Services (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-02-06. Retrieved 2022-07-22.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]