Jump to content

Lateef Akinola Salako

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Lateef Akinola Salako
Ọjọ́ìbí(1935-07-05)5 Oṣù Keje 1935
Lagos State, Nigeria
Aláìsí8 December 2017(2017-12-08) (ọmọ ọdún 82)
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
  • educator
  • pharmacologist
  • therapeuticist
Ìgbà iṣẹ́1935–2017
Àwọn ọmọ
  • Noimot Salako-Oyedele (1966)
  • Tayo Salako (1968)
  • Babajide Salako (1970)
  • Omolara Adetunji (1973)
Awards
NNOM
CON
DSc (Sheffield)

Lateef Akinola Salako NNOM, CON (ọjọ kàrún oṣù keje ọdún 1935 – ọjọ kẹjọ oṣù kejìlá ọdún 2017) jẹ olùmójútó ẹkọ ọmọ orilẹ-ède Nàìjíríà tó jẹ ojogbon elegbogi ati oogun ni Fasiti ìlú Ibadan .

Ìbẹrẹ Ìgbésí ayé

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Lateef Akinola Salako ni ọjọ kàrún oṣù keje ọdún 1945 ni Ipinle Eko, gúúsù ìwọòrùn Naijiria . Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga Methodist Boys, ni Èkó, níbi tí ó ti gba ìwé ẹ̀rí ní West African Senior School ní ọdún 1953. [1] Ó gba ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ní ilé ìwòsàn University College Hospital, Ìbàdàn kó tó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga Fásítì ìlú Sheffield ní ọdún 1969. [2]

Ọdún 1962 lo bẹrẹ iṣẹ rẹ, nílé ìwòsan fásítì ti Ibadan níbi to ti dide sipo ọgá agba ni ọdún 1965, nígbà to si di ọdún 1966 lo di ọmọ ẹgbẹ to n se iwadi nipa ìṣègùn ni Fásítì ìlú Ibadan. O jẹ akẹgbẹ ni Clinical Pharmacology ni ẹka to n mójútó ògùn àti ẹmi, ni Fasiti ìlú Sheffield fun ọdún meji, láàrin ọdún 1967 ati 1969. [3] Ni ọdún 1969, wọn yàn gẹgẹbi Oluko ni Clinical Pharmacology, Fásítì ìlú Ibadan, Ibadan ni ibi ti o ti dide si ipo ti oga olukọni ni ọdún 1977, ati 1970 Ọjọgbọn ni ọdún 1970. Isẹgun Pharmacology. [4] Ni ọdun 1997, o jẹ Alákóso Ile-ẹkọ Imọ-jinlẹ Naijiria lati rọpo Ọjọgbọn Awele Maduemezia . [5]

Salako ku ni ọjọ kẹjọ Oṣu kejila, ọdun 2017, ni ọmọ ọdun mejilélọ́gọrin.

Àmì ẹ̀yẹ ati ọlá

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  • Àmì ẹ̀yẹ ọmọ ìpínlẹ̀ Ogun to lọla, (1990)
  • Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún Ẹ̀yẹ Ọ̀yẹ (1992)
  • Alakoso ti aṣẹ Niger (2004) [6]