Lawan Shettima Ali
Lawan Shettima Ali, (ti a bi ni 15 January 1966), jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè Bursari / Geidam / Yunusari ti Ìpínlẹ̀ Yobe ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà.[1][2][3][4][5]
Ìgbésí àyè ibẹrẹ àti ẹ̀kọ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ali ni wọ́n bi ni ọjọ keedogun Oṣu Kini ọdun 1966. O jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Yobe, ni orílè-èdè Nàìjíríà.[3]
Iṣẹ-ṣiṣe
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ali bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò òṣèlú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Yobe, ó sìn láti ọdún 1991 sí 1993. Ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí Olùdámọ̀ràn Àkànṣe lórí Ọ̀rọ̀ Òṣèlú àti Àpéjọ, fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Yobe, Bukar Abba Ibrahim . Wọ́n yàn án lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC), sínú ilé ìgbìmọ̀ asòfin láti ọdún 2019. Lákòókò Apejọ kẹsàn-án o di ipò igbákejì alága ti Igbimọ Ilé lori ẹ̀rọ ayélujára ati Ọrọ Ilu, ati pe o n ṣiṣẹsin lọwọlọwọ ni ilé ìgbìmò aṣòfin kẹwàá.
Ìṣe
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ali bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò òṣèlú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọmọ ilé igbimọ aṣòfin ìpínlẹ̀ Yobe Yobe State House of Assembly, o sìn gẹ́gẹ́bíi ọmọ ilé ìgbìmò aṣòfin ìpínlẹ̀ náà láti ọdún 1991 sì ọdún 1993. O jẹ olubadamoran pàtàkì lórí ọ̀rọ̀ òṣèlú àti ilé igbimọ aṣòfin ìpínlẹ̀ sì gómìnà ìpínlè Yobe, Bukar Abba Ibrahim. Wọn dibo yàn lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC), si ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà. lákòókò Apejọ kẹsàn-án, wọn yàn gẹ́gẹ́bíi igbákejì alága fún ilé igbimọ aṣòfin àgbà lórí ọ̀rọ̀ ìròyìn àti ará ìlú, ti o sì n sìn lọ́wọ́ lọ́wọ́ ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà ni àpéjọ Kẹ̀wá.[1][5]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 1 2 "National Assembly | Federal Republic of Nigeria". nass.gov.ng. Retrieved 7 January 2025.
- ↑ "ShineYourEye". www.shineyoureye.org. Retrieved 7 January 2025.
- 1 2 "10th National Assembly Members - Voter - Validating the Office of the Electorate on Representation". orderpaper.ng. Retrieved 7 January 2025.
- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 7 January 2025.
- 1 2 Matazu, Hamisu Kabir (8 April 2019). "How we won the 2019 elections in Yobe State – DG, APC Campaign Organisation - Daily Trust". dailytrust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 7 January 2025. Retrieved 7 January 2025.