Jump to content

Michael Omolewa

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Michael Abiola Omolewa
Omolewa in 2022
President of the General Conference of UNESCO
In office
29 September 2003  3 October 2005
AsíwájúAhmad Jalali
Arọ́pòMusa Bin Jaafar Bin Hassan
Permanent Delegate and Ambassador of Nigeria to UNESCO
In office
31 January 2000  31 August 2009
ÀàrẹUmaru Musa Yar'Adua
Olusegun Obasanjo
AsíwájúEmmanuel Olusegun Akinluyi[1]
Arọ́pòMariam Yalwaji Katagum
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí1 Oṣù Kẹrin 1941 (1941-04-01) (ọmọ ọdún 85)
Ipoti-Ekiti, Nigeria
(Àwọn) olólùfẹ́Famata Saptieu Omolewa: née Adams; from The Gambia
Alma materUniversity of Ibadan
University of Dakar
University of London
University of British Columbia

Michael Abiola Omolewa LL-Q34311 (yor)-Tunmise123-Michael Abiola Omolewa.wav Listen ẹni tí a bí ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kẹrin, ọdún 1941 jẹ́ aṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ọ̀mọ̀wé, onímọ̀ nípa ìtàn, àti òṣìṣẹ́ ìjọba.[2] Ó jẹ gẹ́gẹ́ bí Ààrẹ Gbogbogboò kejìlélọ́gbọ̀n ti Àjọ tí ó ń rí sí ètò Ẹ̀kọ́, Ìmọ̀ Sáyẹ́ǹsì àti Àṣà ti Àjọ Àgbáyé - United Nations Educational, Scientific and Cultural Organization (UNESCO).[3] Gẹ́gẹ́ bí Ààrẹ, Ọmọlẹwà ṣojú àjọ UNESCO láti gba Ìkéde Àgbáyé lórí Dátà Ìran Ọmọnìyàn àti Àdéhùn fún Ààbò Àwọn Àṣà Àjogúnbá (International Declaration on Human Genetic Data and the Convention for the Safeguarding of Intangible Cultural Heritage).[4][5] Láti oṣù kìn-ín-ní,ọdún 2000 sí oṣù kẹjọ, ọdún 2009 ni Omolẹwà fi jẹ́ aṣojú àti agbẹnusọ fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sí àjọ UNESCO.[6]Yunifásítì ti Èkó, ní ọjọ́rú, ọjọ́ kẹfà, oṣù kejì, ọdún 2019, Ọmọlẹwà ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ níbi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọdún karùn-ún ti Enoch Adeboye; àkọlé rẹ̀ ni: Àlàáfíà: Ìwádìí Àgbáyé (Peace: The Global Quest). [7][8][9][10][11]



Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Africa in UNESCO". UNESCO. Retrieved 20 September 2012.
  2. "Class of 2008 Michael Omolewa". University of Oklahoma Outreach – College of Continuing Education. Retrieved 7 June 2013.
  3. "Former Presidents of the General Conference". UNESCO. Retrieved 28 August 2012.
  4. "UNESCO ADOPTS A CONVENTION ON THE PRESERVATION OF INTANGIBLE HERITAGE AND A DECLARATION ON HUMAN GENETIC DATA". UNESCO. Retrieved 14 September 2012.
  5. "International Declaration on Human Genetic Data". UNESCO: LEGAL INSTRUMENTS. Retrieved 14 September 2012.
  6. "UNESCO Fears War". Newswatch (Nigeria). Archived from the original on 18 November 2008. Retrieved 12 September 2013. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  7. "Adeboye's birthday lecture fixed for Feb 6". The Cable. 29 January 2019. Retrieved 12 February 2019.
  8. "Adeboye Prays for Peace Again". Vanguard Nigeria. https://www.vanguardngr.com/2019/02/adeboye-prays-for-peace-again.
  9. "Inequalities Threat to Global Peace - ex-Envoy". The Nation Nigeria. Retrieved 12 February 2019.
  10. "UNILAG Hosts 5th Adeboye Annual Birthday Public Lecture: Peace: A Global Quest". Ivory File. Archived from the original on 13 February 2019. Retrieved 12 February 2019.
  11. "UNILAG Hosts Adeboye Lecture". TodayNG. Retrieved 12 February 2019.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]