Jump to content

Mohammed Garba Gololo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Mohammed Garba Gololo jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. o ṣiṣẹ gẹgẹbi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú Gamawa ni ilé ìgbìmò aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà. Wọn bí ni ọdún 1975,o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Bauchi. Wọn kọ́kọ́ diboyan yàn gẹgẹbi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà nínú ìdíje ìdìbò gbogbo gbo ọdún 2015. Wọn tún dibo yàn fún ìgbà kejì nínú ìdíje ìbò ọdún 2019 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC).[1][2]

  1. "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-08.
  2. "National Assembly | Federal Republic of Nigeria". nass.gov.ng. Retrieved 2025-01-08.