Jump to content

Mohammed Idris Malagi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Mohammed Idris Malagi
Mínísítà fún ètò Ìtànkálẹ̀ Àlàyé àti Ìtọ́nisọ́nà Orílẹ̀-Èdè Nàìjíríà
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
Ọjọ kọkànlélógún oṣù kẹjọ ọdún 2023
ÀàrẹBola Tinubu
AsíwájúLai Mohammed
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí
Mohammed Idris

Àdàkọ:Ọjọ ìbí àti ọmọ ọdún
Gbako, Northern Region (now in Niger State), Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress
Education
Occupation
Known forFounder/chairman and publisher of Blueprint

Mohammed Idris ti gbogbo ènìyàn mọ si Malagi (ti a bi ni ọjọ kejì oṣù kàrún ọdún 1966) jẹ olutẹ ìwé jáde ọmọ orilẹ-ede Naijiria, onínúure, olùtajà, alámọ̀dájú ìbátan gbogbo ènìyàn ati olóṣèlú ti o jẹ Minisita fún ètò Alaye ati Iṣalaye Orilẹ-ede Nàìjíríà. Ààrẹ Bola Tinubu yán an ni osu kẹjọ ọdún 2023. Òun ni Olùdásílẹ̀/alága ati akéde <i id="mwEA">Blueprint</i> . O tún jẹ alága ti Kings Broadcasting Limited ti o wa ni Abuja, awọn ti ó ni WE 106.5 FM Abuja, Nàìjíríà. [1] Ó jẹ́ akọ̀wé àgbà fún Ẹgbẹ́ Àwọn Oníṣẹ́ Ìròyìn ti Nàìjíríà . [2] [3] Ni àfikún, o di ipo Olùdarí Àwọn ibaraẹnisọrọ ọlọgbọn fun Ìgbimọ Ipolongo Alàkóso ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress ti ẹgbẹ́ ìpolongo fún ààrẹ Tinubu-Shettima. [4]

Ìbẹrẹ Ìgbésí ayé ati ẹkọ

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bi Mohammed Idris ni ọjọ kejì oṣù karùn-ún ọdún 1966 ni ijoba ibile Gbako ni Ipinle Niger . O lọ ilè ekọ alákọbẹ̀rẹ̀ re ni Kontagora láàrin ọdún 1971 si 1977. O si lo si GSS Rijau ni ọdún 1977 o si gboyè jáde ni ọdún 1982. Ni ọdún 1983 wọn gbà wọlé láti kọ ẹkọ nípa ede gẹ̀ẹ́sì ni Fasiti Usmanu Danfodiyo, Sokoto, níbi ti o ti jáde ni ọdún 1987. O si tun kẹkọ parí nibi iyẹwu kejì pẹlú ẹkọ kannáà sí ti isaaju ni Fasiti Kano9 ni ọdún 1995.[5]

Ni Oṣù Kàrún ọdún 2011, Idris Malagi dasile iṣẹ <i id="mwMg">Blueprint</i> silẹ, ìwé ìròyìn ti o njade ni ọsẹ ati lojojumọ ni èdè Gẹẹsi ati èdè Hausa ti a pe ni Manhaja. [6] Malagi ti jẹ alága ati olùdarí àgbà lati ibẹrẹ rẹ. O tun jẹ Olùdásílẹ̀ ati alága ti Ẹgbẹ Bifocal. [7] Ni Oṣu Kejìlá ọdún 2020, o jẹ akọ̀we gbogbogbò ti Ẹgbẹ Awọn Olùdásílẹ̀ Iwe Iroyin ti Nigeria . [8] [9] Ni ọjọ kẹtàdínlọ́gbọ̀n Oṣù kọkànlá, ọdún 2019, o gba agbára níni Kings Broadcasting Network, awọn ti wọn ni WE 106.5 FM Abuja. [10]

Mohammed Idris Malagi, gẹ́gẹ́ bí ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, jẹ́ olùdíje ipò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Niger fún ìdìbò gbogbogbò Nàìjíríà 2023 . [11] O rọ ibò 154 ati pe o pàdánù si ọmọ ẹgbẹ ti Ile Awọn Aṣojú àpapọ, Umar Bago ti o ri ibò 386. [12] [13] Wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bí Olùdarí Ìsọfúnni-Ọ̀rọ̀ ọlọgbọn fún ẹgbẹ́ ìpolongo ààrẹ Asiwaju Bola Ahmed Tinubu. [14] [15]

Àmì ẹ̀yẹ àti ìdánimọ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Alhaji Mohammed Idris Malagi ni oyè ibile Kakaaki Nupe, oyè ti Yahaya Abubakar, Etsu Nupe(Ọba tápà) fi fún un. Àkọlé náà ṣe ìdánimọ̀ ifẹnukonu àti àwọn àṣeyọrí ti ara ẹni ni ìpele ayélujára ati ààyè ìbátan gbogbo ènìyàn. [16] Ni ọjọ kẹjọ Oṣu Kejìlá ọdún 2022, o gba ami-ẹyẹ̀ ti Milestone ìdánimọ̀ ti ayélujára ni Nàìjíríà nipasẹ Ẹgbẹ Awọn Akoroyin Naijiria . [17]

  1. https://newcitizen.ng/malagi-a-frontrunners-6-guidelines-to-power/%5B%5D
  2. https://www.blueprint.ng/blueprint-publisher-now-npan-scribe-as-trust-chair-leads-new-team/
  3. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2023-07-12. Retrieved 2025-08-12.
  4. https://newcitizen.ng/2023-elections-blueprint-publisher-malagi-joins-tinubu-campaign-as-communications-director/%5B%5D
  5. https://prnigeria.com/2020/05/10/mohammed-idris-54-pr/
  6. https://dailynigerian.com/mohammed-idris-blueprint/
  7. https://www.blueprint.ng/9-years-on-i-feel-significantly-accomplished-blueprints-publisher/
  8. https://www.blueprint.ng/blueprint-publisher-now-npan-scribe-as-trust-chair-leads-new-team/
  9. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2023-07-12. Retrieved 2025-08-12.
  10. https://www.blueprint.ng/blueprint-publisher-idris-takes-over-we-fm-radio/#:~:text=A%20Public%20Relations%20expert%20and,relaunch%20dinner%20held%20Wednesday%20night.
  11. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2024-06-16. Retrieved 2025-08-12.
  12. https://www.channelstv.com/2022/05/27/reps-member-umaru-bago-wins-niger-apc-governorship-primary/
  13. https://dailypost.ng/2022/05/27/house-of-reps-member-bago-emerges-niger-apc-gubernatorial-candidate/
  14. https://tribuneonlineng.com/tinubu-inaugurates-presidential-campaign-offfice-donated-by-malagi-in-minna/
  15. https://web.archive.org/web/20221020151557/https://www.thecable.ng/wp-content/uploads/2022/10/TINUBU-SHETTIMA-2023-PCC.pdf
  16. https://newcitizen.ng/2023-elections-blueprint-publisher-malagi-joins-tinubu-campaign-as-communications-director/%5B%5D
  17. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2024-12-11. Retrieved 2025-08-12.