Mohammed Omar Bio
Ìrísí
Mohammed Omar Bio jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. O jẹ ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú Baruten/Kaiama ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà. Won bí ní ọjọ́ kejì oṣù kẹfà ọdún 1964, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Kwara State. Wọn kọ́kọ́ yàn sì ilé igbimọ aṣòfin ni ọdún 2019, won tún dibo yàn ni ọdun 2023 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress(APC).[1][2][3]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "10th National Assembly Members - Voter - Validating the Office of the Electorate on Representation". orderpaper.ng. Retrieved 2025-01-08.
- ↑ "National Assembly | Federal Republic of Nigeria". nass.gov.ng. Retrieved 2025-01-08.
- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-08.