Jump to content

Mohammed Yusuf (Boko Haram)

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Mohammed Yusuf
Fáìlì:Mohammed-Yusuf.jpg
Born(1970-01-29)29 Oṣù Kínní 1970
Jakusko, North-Eastern State, Nigeria (today Yobe)
Died30 July 2009(2009-07-30) (ọmọ ọdún 39)
Maiduguri, Borno, Nigeria
AllegianceBoko Haram
Years of service2002–2007
RankLeader
Battles/warsBoko Haram insurgency

Mohammed Yusuf (29 January 1970 – 30 July 2009), ti àwọn èèyàn mo sì Ustaz Mohammed Yusuf, jẹ ọmọ àgbèsùnmọ̀mí ni orílè-èdè Nàìjíríà ti odá ìjọ Islamist ti ológun kalẹ Boko Haram in ọdún 2002. O jeadarí iko náà di ìgbà tí wọ́n fi pá ni ọdun 2009.[1]

Won bi ni abúlé Girgi, ní Jakusko, ni ìpínlè Yobe , Nàìjíríà, Yusuf kàwé ni ilé ìwé gíga yunifasiti.[2] Lẹ́yìn náà o kò nípa ẹṣin Islam to òsì di Salafi.[3]

Ẹkọ àti ìgbàgbọ́

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Gẹgẹbi ọjọgbọn Paul Lubeck ti University of California ni Santa Cruz, gẹ́gẹ́bí ọdọ ọmọdé Yusuf ti wọn pá ni àṣẹ pẹ̀lú ìbámu Shia Islam ati ni ìbámú pẹ̀lú Salafism àti ẹ̀kọ́ Ibn Taymiyyah.[4] Oni ìwé ẹ̀rí tí o ṣé dédé ẹniti o losi ilẹ̀ ìwé gíga yunifasiti, ni ìbámú pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ọjọgbọn Hussain Zakaria. Yusuf ko gbo èdè Gẹẹsi gẹgẹbi wọn se ròyìn ree tó. O ni igbagbọ wípé òfin Islam nìkan ni òfin èyítí o bá igbagbọ rẹ mú ni ìlànà ti Ojisẹ ẹṣin Islam se ko wọn, Muhammad. Boko Haram má ń pá àwọn elesin Islam be tí wọ́n ṣùgbọ́n ti igbagbọ won yàtò sì ti wọn be Salafist Izala àti Sufi Tidjaniyyapẹ̀lú Qadiriya fraternities.[5] Ni ọdun 2009 BBC se ifi ọ̀rọ̀ wani lénu wo, Yusuf so wípé igbagbọ science nípa wípé ayé rí rogodo takò igbagbọ ẹṣin ti ko si yẹ ki o dì ìtẹ́wọ́gbà. O tun takò ìṣe ìwádìí Darwinian nípa ayé , àti bi science se ṣàlàyé bi ojo se n rò.[6] o sọ nínú ifi ọ̀rọ̀ wani lénu wo wípé:

There are prominent Islamic preachers who have seen and understood that the present Western-style education is mixed with issues that run contrary to our beliefs in Islam, he said.

Like rain. We believe it is a creation of God rather than an evaporation caused by the sun that condenses and becomes rain.

Be àpẹẹrẹ wípé ayé ri róbótó. ti o bá tí yàtò sì ohùn ti Ọlọhun wi a o lòdì ṣii. Asi to ìṣeìwádìí Darwinism

Yusuf ni ìyàwó mẹrin pẹ̀lú ọmọ mọ́kànlá,[7] ti ọkan lára wọn n jẹ Abu Musab al-Barnawi, ti o fi idire múlẹ̀ wípé ohùn ni adarí àwọn musulumi láti ọdún 2016 àti ẹniti o tó láti jẹ olórí àwọn Boko-haram takò Abubakar Shekau.[8]

Won jẹ ko yẹ wá wípé ohun jẹ ayé familete kin tuto, ti o sì ni ọkọ ayokele Mercedes-Benz.[6]

Leyin July ọdun 2009 Boko Haram ti ngbo ro , àwọn ọmọ ológun orí ilé orílè-èdè Nàìjíríà mu Yusuf. Won fi ṣòwò sì akoto àwọn olopaa.[9] àwọn olopaa ìbon fún fún Yusuf in ìta gbàǹgbà iwájú ilé olopaa ni Maiduguri.[10][11][12] Àwọn olopaa kókóso wípé Yusuf ni wọn yín ìbọnfún nígbà on gbìyànjú láti salo tàbí kó jẹ wípé ojú ogbe ìbon látàrí ifi iga gbà ìgbà pẹ̀lú àwọn ọmọ ológun kí ọwọ to tẹ.[11][12]

  1. Boko Haram: The Emerging Jihadist Threat in West Africa – Background, Anti-Defamation League, 12 December 2011.
  2. Militancy and Violence in West Africa: Religion, politics and radicalisation edited by James Gow, Funmi Olonisakin, Ernst Dijxhoorn, ISBN 9780415821377, via books.google.co.uk, page 74
  3. Dowd, Robert A. (1 July 2015) (in en). Christianity, Islam, and Liberal Democracy: Lessons from Sub-Saharan Africa. Oxford University Press. p. 102. ISBN 9780190225216. https://books.google.com/books?id=v7C6BwAAQBAJ.
  4. Johnson, Toni (27 December 2011). "Backgrounder – Boko Haram". www.cfr.org. Council of Foreign Relations. Retrieved 12 March 2012.
  5. Vicky, Alain (1 April 2012). "Aux origines de la secte Boko Haram". Le Monde diplomatique (in Èdè Faransé). Retrieved 4 December 2019.
  6. 1 2 "Nigeria's 'Taliban' enigma". BBC News. 28 July 2009. http://news.bbc.co.uk/2/low/africa/8172270.stm.
  7. "Nigeria sect head dies in custody". BBC News. BBC. 31 July 2009. http://news.bbc.co.uk/2/hi/africa/8177451.stm.
  8. "Shekau Resurfaces, Accuses New Boko Haram Leader al-Barnawi Of Attempted Coup". 360nobs. 4 August 2016. Archived from the original on 17 July 2018. Retrieved 16 July 2018. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  9. "Nigeria row over militant killing". BBC News. 31 July 2009. http://news.bbc.co.uk/2/hi/africa/8178820.stm.
  10. Adam Nossiter; David D. Kirkpatrick (7 May 2014). "Abduction of Girls an Act Not Even Al Qaeda Can Condone". The New York Times. https://www.nytimes.com/2014/05/08/world/africa/abduction-of-girls-an-act-not-even-al-qaeda-can-condone.html?_r=0.
  11. 1 2 Human Rights Watch (11 October 2012). "Spiraling Violence: Boko Haram Attacks and Security Force Abuses in Nigeria". Human Rights Watch. https://www.hrw.org/reports/2012/10/11/spiraling-violence-0. Retrieved 27 June 2015.
  12. 1 2 "Video shows Nigeria 'executions'". Al Jazeera. 9 February 2010. http://www.aljazeera.com/news/africa/2010/02/2010298114949112.html.