Jump to content

Muhammad Umar Jega

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Muhammad Umar Jega jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. tinsójú àgbègbè ẹkùn ìdìbò Aleiro/Gwandu/Jega ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà. Wọn bí ní ọdún 1959, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Kebbi. O rọ́pò Ibrahim Aliyu Gwandu ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà ti wọn dibo yàn nínú ètò ìdìbò gbogbo gbo ọdún 2007, wọn tún yàn fún ìgbà kejì ní ọdún 2015, àti fún ìgbà kẹta ni ọdún 2019 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC).[1] He secured the party ticket to contest at the 2023 elections after a Supreme Court ruling.[2] O ṣiṣẹ gẹgẹbi alága ilé igbimọ aṣòfin lórí ọrọ àwọn tí ogún sì ni di padà, arìnrìn-àjò àti àwọn tí wọ́n fẹ́ fi ará pamọ sì orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Nínú ọpọlọpọ awọn iṣẹ àkànṣe rẹ, o pèsè ohùn èlò ẹ̀kọ́ àti ìwòsàn fún àwon ènìyàn rẹ.[3]

  1. "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-07.
  2. "APC Aliero/Gwandu/Jega Reps Seat: Supreme Court Upholds Muhammad Jega's Candidacy – Independent Newspaper Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2023-01-21. Retrieved 2025-01-07.
  3. "Feb 25: How Hon. Umar Jega Fared in the 9th National Assembly". THE LEGISLATURE (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2023-02-22. Retrieved 2025-01-07.