Musa Tsamiya Ado
Musa Tsamiya Ado | |
|---|---|
| Member of the House of Representatives | |
| In office 2011–2019 | |
| Constituency | Gezawa/Gabasawa Federal Constituency |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 30 May 1967 Kano State, Nigeria |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressives Congress |
| Occupation | Politician |
Musa Tsamiya Ado jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà láti ìlú Kano tinsójú àgbègbè ẹkùn ìdìbò Gezawa /Gabasawa àpapọ̀ ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà. Wọn kọ́kọ́ diboyan gẹgẹbi ọmọ ẹgbẹ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP) sì ilé igbimọ aṣòfin àgbà ti o sìn láàárín ọdún 2011 si ọdún 2015. Ni ọdun 2015, wọn tún dibo yàn sì ilé igbimọ aṣòfin apapọ lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC) ti o sì sìn títí di ọdún 2019.[1][2]
Ìgbésí àyè ibẹrẹ àti ẹ̀kọ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Musa Tsamiya Ado ni wọ́n bi ni ọgbọ́n ọjọ́ oṣù karùn-ún ọdún 1967, ni ìpínlè Kano, Nigeria. O parí ẹ̀kọ́ rẹ ní ilé ìwé olùkọ́ni Teacher's College ni ìlú Kano, nibiti o tí gbà ìwé ẹ̀rí Grade II.[3][1]
Ìrìnàjò òṣèlú
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Musa Tsamiya Ado ni wọ́n kọ́kọ́ diboyan ni 2011 láti sójú ẹkùn idibo Gezawa/Gabasawa nílé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà lábé ẹgbẹ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP) láàrin ọdún 2011 si ọdún 2015. Wọ́n tún dibo yàn ni ọdun 2015 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC) tí o sì sìn di ọdún 2019.[1][3] ohùn ní oropo Abduwa Gabasawa Nasiru tí Mahmoud Mohammed náà sì rọ́pò ohùn náà nínú ìdíje ètò ìdìbò ọdún 2023.[1] Gómìnà Abba Yusuf yàn gẹgẹbi Oludamoran pàtàkì lórí ọ̀rọ̀ gada ni ọdun 2023.[4][5][6]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 1 2 3 4 "Citizen Science Nigeria". Citizen Science Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-07.
- ↑ "12 Kano reps deny endorsing Ganduje - Daily Trust". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2016-03-24. Retrieved 2025-06-05.
- 1 2 "Hon. Musa Ado biography, net worth, age, family, contact & picture". Manpower Nigeria. Retrieved 2025-01-07.
- ↑ Abubakar Ahmadu Maishanu. "Nigerian governor appoints 97 special advisers, assistants". Premium Times. Retrieved 2025-06-05.
- ↑ Agbana, Rotimi (2023-08-07). "BREAKING: Kano gov appoints heads of agencies, SAs". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-06-05.
- ↑ "Governor Abba Kabir Appoints Baba Umar Special Adviser Private Schools, 9 other SAs - INDEPENDENT POST NIGERIA" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2023-08-07. Retrieved 2025-07-25.