Jump to content

Musa Tsamiya Ado

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Musa Tsamiya Ado
Member of the House of Representatives
In office
2011–2019
ConstituencyGezawa/Gabasawa Federal Constituency
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí30 May 1967
Kano State, Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress
OccupationPolitician

Musa Tsamiya Ado jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà láti ìlú Kano tinsójú àgbègbè ẹkùn ìdìbò Gezawa /Gabasawa àpapọ̀ ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà. Wọn kọ́kọ́ diboyan gẹgẹbi ọmọ ẹgbẹ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP) sì ilé igbimọ aṣòfin àgbà ti o sìn láàárín ọdún 2011 si ọdún 2015. Ni ọdun 2015, wọn tún dibo yàn sì ilé igbimọ aṣòfin apapọ lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC) ti o sì sìn títí di ọdún 2019.[1][2]

Ìgbésí àyè ibẹrẹ àti ẹ̀kọ́

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Musa Tsamiya Ado ni wọ́n bi ni ọgbọ́n ọjọ́ oṣù karùn-ún ọdún 1967, ni ìpínlè Kano, Nigeria. O parí ẹ̀kọ́ rẹ ní ilé ìwé olùkọ́ni Teacher's College ni ìlú Kano, nibiti o tí gbà ìwé ẹ̀rí Grade II.[3][1]

Ìrìnàjò òṣèlú

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Musa Tsamiya Ado ni wọ́n kọ́kọ́ diboyan ni 2011 láti sójú ẹkùn idibo Gezawa/Gabasawa nílé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà lábé ẹgbẹ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP) láàrin ọdún 2011 si ọdún 2015. Wọ́n tún dibo yàn ni ọdun 2015 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC) tí o sì sìn di ọdún 2019.[1][3] ohùn ní oropo Abduwa Gabasawa Nasiru tí Mahmoud Mohammed náà sì rọ́pò ohùn náà nínú ìdíje ètò ìdìbò ọdún 2023.[1] Gómìnà Abba Yusuf yàn gẹgẹbi Oludamoran pàtàkì lórí ọ̀rọ̀ gada ni ọdun 2023.[4][5][6]

  1. 1 2 3 4 "Citizen Science Nigeria". Citizen Science Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-07.
  2. "12 Kano reps deny endorsing Ganduje - Daily Trust". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2016-03-24. Retrieved 2025-06-05.
  3. 1 2 "Hon. Musa Ado biography, net worth, age, family, contact & picture". Manpower Nigeria. Retrieved 2025-01-07.
  4. Abubakar Ahmadu Maishanu. "Nigerian governor appoints 97 special advisers, assistants". Premium Times. Retrieved 2025-06-05.
  5. Agbana, Rotimi (2023-08-07). "BREAKING: Kano gov appoints heads of agencies, SAs". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-06-05.
  6. "Governor Abba Kabir Appoints Baba Umar Special Adviser Private Schools, 9 other SAs - INDEPENDENT POST NIGERIA" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2023-08-07. Retrieved 2025-07-25.