Nadine Ibrahim
Nadine Ibrahim | |
---|---|
Ọjọ́ìbí | Àdàkọ:Birth based on age as of date Kaduna |
Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
Iléẹ̀kọ́ gíga | University of Gloucestershire |
Iṣẹ́ | Film director |
Ìgbà iṣẹ́ | 2015-present |
Nadine Ibrahim (tí a bí ní ọdún 1993/1994 ) jẹ́ olùdarí eré ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ìsẹ̀mí rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
A bí Ibrahim ní ìlú Kaduna ó sì dàgbà sí inú ẹ̀sìn Mùsùlùmí. Ìyá rẹ̀ tí orúkọ rẹ̀ n ṣe Amina J. Mohammed ti fìgbà kan jẹ́ òjíṣẹ́ ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà rìí fún ètò àyíká.[1] Láti ìgbà tí ó ti wà lọ́mọdé ni ó ti ní ìfẹ́ sí ṣíṣe fíìmù.[2] Ó kó lọ sí Ilẹ̀ọba Aṣọ̀kan nígbà tí ó wà lọ́mọ ọdún mẹ́rìnlá[3] níbi tí ó ti kẹ́kọ̀ọ́ ṣíṣe fíìmù láti ilé-ẹ̀kọ́ gíga Gloucestershire University. Ó tún maá n ṣiṣẹ́ lóri àwọn iṣẹ́ àkànṣe fún Ajo Agbaye pẹ̀lú ṣíṣe àwọn fíìmù tó dá lóri ìrírí ayé. Ibrahim jẹ́ ọ̀kan lára àwọn tí wọ́n gbé eré tí àkọ́lé rẹ̀ jẹ́ Hakkunde jáde. Eré náà dá lóri ará Gúúsù Nàìjíríà kan tí ó ṣe alábàápàdé àṣà Ariwa fún ìgbà àkọ́kọ́.[4]
Ibrahim tọ́ka sí Tyler Perry, Alfred Hitchcock, Spike Lee àti Ang Lee gẹ́gẹ́bi àwọn àwòkọ́ṣe rẹ̀.[5]Ó tún tọ́ka sí ìyá rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ẹni tí ó tún ní ipa pàtàkì lóri rẹ̀.[2] Wọ́n dárúkọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ọ̀kan lára àwọn ọ̀dọ́ olùbéréjáde tí ó ní ìlérí jùlọ ní Nàìjíríà.[6] Ibrahim ṣe ìgbeyàwó pẹ̀lú Nasir ní ìlú Àbújá ní ọdún 2014.[7]
Àṣàyàn àwọn eré rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- 2015: Idéar (short film)
- 2017: Hakkunde (short film)
- 2017: Through Her Eyes (short film)
- 2018: Tolu (short film)
- 2019: I am not corrupt (short film)
- 2019: Marked (short film)
- 2019: Words cut deep (short film)
Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ "Nadine Ibrahim: I want to tell stories that can change the world". 4 March 2017. https://guardian.ng/guardian-woman/nadine-ibrahim-i-want-to-tell-stories-that-can-change-the-world/. Retrieved 11 October 2020.
- ↑ 2.0 2.1 "In Conversation with Nigerian Filmmaker Nadine Ibrahim: 'The local stories matter the most.'". 22 October 2019. https://www.okayafrica.com/nadine-ibrahim-film-nigeria-nollywood/. Retrieved 11 October 2020.
- ↑ "Lessons on Breaking into the movie industry- Nadine Ibrahim Films to the world.". MRSCEONAIJA. 25 February 2018. Archived from the original on 29 October 2021. Retrieved 11 October 2020.
- ↑ "The Future Awards Africa Prize for Screen Producer". The Future Awards Africa. 2 December 2018. Retrieved 11 October 2020.
- ↑ "Nigerian filmmaker Nadine Ibrahim talks about the essence of being different". Pulse. 16 August 2019. https://www.pulse.ng/bi/lifestyle/nadine-ibrahim-nigerian-filmmaker-talks-about-the-essence-of-being-different/nzp71n0. Retrieved 11 October 2020.
- ↑ "Three Young Nigerian Filmmakers to Watch". Shadow and Act. 8 May 2017. Retrieved 11 October 2020.
- ↑ "Nadine Ibrahim: The Beautiful Daughter Of Amina J. Muhammad". Opera News. Archived from the original on 13 October 2020. Retrieved 11 October 2020.