Jump to content

National Universities Commission

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

National Universities Commission ti adape rẹ ni jẹ (NUC) jẹ àwùjọ ìjọba àpapò orílè-èdè Nàìjíríà tí wọ́n ṣe agbekalẹ rẹ láti lè mọ ṣe àmójútó àti ìṣàkóso pẹ̀lú ìdásílẹ̀ àwọn ilé ìwé ẹ̀kọ́ gíga ti a mọ sì higher education ni orílè-èdè Nàìjíríà. NUC, gẹ́gẹ́bíi wọn ṣe mọ̀n pé, wọn ṣe idasile rẹ ní ọdún 1962 gẹ́gẹ́bíi àwùjọ èyítí yíò mọ gbà ìjọba ní ìmọ̀ràn.[1] Ni ọdún 1974, o di àwùjọ èyítí o da dúró láti lè pàṣẹ fún ará rẹ ẹni tí ó kọ́kọ́ jẹ olùdarí àwùjọ náà ní ọjọgbọn Jibril Aminu.[1][2] NUC wá labẹ ìṣàkóso Federal Ministry of Education ti o sí jẹ ẹka parastatal (èyítí o jẹ wípé ìjọba lónìí).[3]

  1. 1 2 "About Us". www.nuc.edu.ng. National Universities Commission. Retrieved 2020-05-25.
  2. Akinwumi, Femi S. (2009-01-01). Roles of Educational Agencies in Nigerian Educational System. https://www.academia.edu/43736606.
  3. Abubakar, Bappah (2011-01-01). "Academic Libraries in Nigeria in the 21st Century". Library Philosophy and Practice (E-journal). https://digitalcommons.unl.edu/libphilprac/446.