Jump to content

Noheem Babatunde Adams

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Noheem Babatunde Adams
Member of the Lagos State House of Assembly
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
18 March 2023
Majority Leader of the Lagos State House of Assembly
from Eti-Osa Local Government
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
18 March 2023
ConstituencyEti-Osa 1
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí15 Oṣù Kẹrin 1980 (1980-04-15) (ọmọ ọdún 46)
Eti-Osa, Eti-Osa Local Government Lagos State Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressive Congress
EducationLagos State University
Alma mater
Occupation
  • Politician
  • Project Manager
  • Administrator
  • Tax Consultant

Noheem Babatunde Adams jẹ oludamọran lórí ọ̀rọ̀ owo-ori àti olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà tí o ń ṣojú àgbègbè Eti-Osa I, ni ijọba ìbílè Eti-Osa ni Ile-igbimọ aṣofin ìpínlè Eko.[1][2][3]

Ìgbésí aye ibẹrẹ ati ẹkọ

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bi Noheem ni 15 Oṣu Kẹrin ọdún 1980 ni Ìpínlẹ̀ Eko, ní orílè-èdè Nàìjíríà. O ti gbà ìwé ẹ̀rí ni ilé ìwé ẹ̀kọ́ gíga Yunifásítì Lagos State University (LASU), níbi ti o ti ko ẹ̀kọ́ nípa ìmò sayensi òṣèlú àti International Relations ati Strategic Studies lẹsẹsẹ.[4]

Noheem jẹ alákòóso ati oludamọran lórí ọ̀rọ̀ owo-ori ti o darapọ mọ ìṣèlú, o ti ṣiṣẹ tẹlẹ gẹ́gẹ́bíi alákòóso ni àgbègbè Eti-Osa ni Ìpínlẹ̀ Eko ṣáájú ìdìbò rẹ gẹ́gẹ́bíi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin keje ni Ìpínlè Eko labẹ ẹgbẹ òṣèlú All Progressive Congress nínú ètò ìdìbò gbogboogbo ọdún 2015.[4]

  1. "Hon. Noheem Babatunde Adams – Lagos House Of Assembly" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2024-06-18. Retrieved 2025-12-03.
  2. "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.
  3. Oloniniran, Gbenga (2025-09-04). "Constituency meeting: Lagos lawmaker empowers residents". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.
  4. 1 2 "LeaderBox - Political Leadership Platform". leaderbox.africa (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.