Noheem Babatunde Adams
Ìrísí
Noheem Babatunde Adams | |
|---|---|
| Member of the Lagos State House of Assembly | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
| Ó gun orí àga 18 March 2023 | |
| Majority Leader of the Lagos State House of Assembly from Eti-Osa Local Government | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
| Ó gun orí àga 18 March 2023 | |
| Constituency | Eti-Osa 1 |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 15 Oṣù Kẹrin 1980 Eti-Osa, Eti-Osa Local Government Lagos State Nigeria |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressive Congress |
| Education | Lagos State University |
| Alma mater | |
| Occupation |
|
Noheem Babatunde Adams jẹ oludamọran lórí ọ̀rọ̀ owo-ori àti olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà tí o ń ṣojú àgbègbè Eti-Osa I, ni ijọba ìbílè Eti-Osa ni Ile-igbimọ aṣofin ìpínlè Eko.[1][2][3]
Ìgbésí aye ibẹrẹ ati ẹkọ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]A bi Noheem ni 15 Oṣu Kẹrin ọdún 1980 ni Ìpínlẹ̀ Eko, ní orílè-èdè Nàìjíríà. O ti gbà ìwé ẹ̀rí ni ilé ìwé ẹ̀kọ́ gíga Yunifásítì Lagos State University (LASU), níbi ti o ti ko ẹ̀kọ́ nípa ìmò sayensi òṣèlú àti International Relations ati Strategic Studies lẹsẹsẹ.[4]
Iṣẹ-ṣiṣe
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Noheem jẹ alákòóso ati oludamọran lórí ọ̀rọ̀ owo-ori ti o darapọ mọ ìṣèlú, o ti ṣiṣẹ tẹlẹ gẹ́gẹ́bíi alákòóso ni àgbègbè Eti-Osa ni Ìpínlẹ̀ Eko ṣáájú ìdìbò rẹ gẹ́gẹ́bíi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin keje ni Ìpínlè Eko labẹ ẹgbẹ òṣèlú All Progressive Congress nínú ètò ìdìbò gbogboogbo ọdún 2015.[4]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Hon. Noheem Babatunde Adams – Lagos House Of Assembly" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2024-06-18. Retrieved 2025-12-03.
- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.
- ↑ Oloniniran, Gbenga (2025-09-04). "Constituency meeting: Lagos lawmaker empowers residents". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.
- 1 2 "LeaderBox - Political Leadership Platform". leaderbox.africa (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.