Oga Bello
Ìrísí

Wón bi Adébáyò Sàlámì
Listen tí gbọgbọ ènìyàn mòn pẹ̀lú orúkọ eré ìtàgé wọn "Oga Bello" Ó jẹ́ ògbólógbòó òṣèré nollywood ní Nàìjíríà, tí otun je olùdarí àti alágbè jáde eré àgbéléwò.
Ìgbésí ayé àti ipilese Èkó
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ọmọ bíbí ìlú Pàkátà Olóje, Ilorin, ni ipinle Kwara ni Sàlámì, wọ́n bi ní ọjọ́ Kẹ̀sán oṣù karùn-ún ọdún 1953 ní ipinle Eko níbi tó ti kó ẹ̀kọ́ alákoberẹ̀ àti girama. [1]
Adébáyò Sàlámì lọ sí Adebodun Commercial School, o si lọ sí Lagos Drama School, ilé-ìwé tí o somọ Pẹ̀lú University of Lagos .