Jump to content

Olúwafémi Ajísafé

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Òjògbón Micheal Olúwafémi Ajísafé jé ọmọ Nàìjíríà ómówè, àlárà ere ìdárayá àti Board of Trustees (BOT) àti Council of Afé Babalola University, Ado-Ekiti (ABUAD), tí yan Òjògbón Michael O. Ajísafé, gẹ́gẹ́ bi igbákejì ògá àgbà ile ìwé gíga yùnìfásitì ọlódún mẹ́rin ti yoo bẹ̀rẹ̀ láti Oṣù Seere, ọjọ́ Kàrún , 2014.

Èyí jẹ́ àbájáde ní ìparí ọdún mẹ́rin tí Igbákejì Alákóso aṣáájú-ọnà, Òjògbón, Sídí Osho, ní Oṣù Kínní Ọjọ́ Kẹrin, Ọdun 2014. Lẹ́yìn náà ni wón yàn án gẹ́gẹ́ bi igbákejì kánsélò fasiti Afe Babalola, Ado Ekiti, ni ipò tí o di láàrin ọjọ́ Kínní oṣù kẹwàá ọdún 2015 sí ọjọ́ kokànlélógún oṣù kẹfà ọdún 2019. Ó tún jẹ́ Òjògbón àkókó ti Ìmọ̀-iṣé Eré ìdárayá àti Èkó tí àrà ní Nàìjíríà.[1][2][3]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Professor M.O. Ajisafe is Chief Resource Consultant! - Afe Babalola University". Afe Babalola University. 6 July 2011. Retrieved 8 April 2018.
  2. "Vice Chancellor - Afe Babalola University". Afe Babalola University. Retrieved 8 April 2018.
  3. "Michael Olufemi Ajisafe - Google Scholar Citations". scholar.google.com. Retrieved 8 April 2018.