Olúwafémi Ajísafé
Ìrísí
Òjògbón Micheal Olúwafémi Ajísafé jé ọmọ Nàìjíríà ómówè, àlárà ere ìdárayá àti Board of Trustees (BOT) àti Council of Afé Babalola University, Ado-Ekiti (ABUAD), tí yan Òjògbón Michael O. Ajísafé, gẹ́gẹ́ bi igbákejì ògá àgbà ile ìwé gíga yùnìfásitì ọlódún mẹ́rin ti yoo bẹ̀rẹ̀ láti Oṣù Seere, ọjọ́ Kàrún , 2014.
Èyí jẹ́ àbájáde ní ìparí ọdún mẹ́rin tí Igbákejì Alákóso aṣáájú-ọnà, Òjògbón, Sídí Osho, ní Oṣù Kínní Ọjọ́ Kẹrin, Ọdun 2014. Lẹ́yìn náà ni wón yàn án gẹ́gẹ́ bi igbákejì kánsélò fasiti Afe Babalola, Ado Ekiti, ni ipò tí o di láàrin ọjọ́ Kínní oṣù kẹwàá ọdún 2015 sí ọjọ́ kokànlélógún oṣù kẹfà ọdún 2019. Ó tún jẹ́ Òjògbón àkókó ti Ìmọ̀-iṣé Eré ìdárayá àti Èkó tí àrà ní Nàìjíríà.[1][2][3]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Professor M.O. Ajisafe is Chief Resource Consultant! - Afe Babalola University". Afe Babalola University. 6 July 2011. Retrieved 8 April 2018.
- ↑ "Vice Chancellor - Afe Babalola University". Afe Babalola University. Retrieved 8 April 2018.
- ↑ "Michael Olufemi Ajisafe - Google Scholar Citations". scholar.google.com. Retrieved 8 April 2018.