Jump to content

Olajide Jimoh

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Olajide Abdul Jimoh jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. O jẹ ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè ẹkùn ìdìbò Lagos MMainland ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà. Wọn bí ni ọdun 1961, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Ẹ̀kọ́. Wọn kọ́kọ́ diboyan yàn gẹgẹbi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà nínú ètò ìdìbò gbogbo gboọdún 2015, wọn tún dibo yàn fún ìgbà kejì ní ọdún 2019 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress(APC).[1][2] Láti ṣe iranlọwọ fún àwọn ẹ̀yán rẹ, o pèsè ohùn èlò ẹ̀kọ́ àti èrò alupupu fún àwọn ènìyàn ẹkùn ìdìbò rẹ.[3]

  1. "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 8 January 2025.
  2. "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 8 January 2025.
  3. "Lawmaker, Jimoh empowers youths, women in Lagos". Starconnect media. 24 February 2020. Retrieved 8 January 2025.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]