Olatayo Amokade
Ìrísí
Olatayo Amokade tàbí Táyọ̀ Amọ̀kádé tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ìjẹ̀bú (tí wọ́n bí lọ́jọ́ 5 May, 1979) jẹ́ òṣèré sinimá àgbéléwò ọmọ Ìlisàn-Rẹ́mọ, Ìjẹ̀bú, ní ìpínlẹ̀ Ògùn lórílẹ̀-èdè Nigeria.[1]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Fasan, Yewande (2025-04-23). "Actor Ijebu unveils multi-million naira lounge in Ogun, receives massive support". The Nation Newspaper. Retrieved 2025-11-04.