Olufunlola Adekeye
Onídajo Olufunlola Oyelola Adekeye jẹ adajọ Nàìjíríà. Òun ní obìnrin Kejì ti wọn o yan gẹgẹ bi Adajọ Idajọ ti Ile-ẹjọ giga julọ ti Nigeria (JSC). [1] [2]
Ìgbésí ayé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Adekeye lọ si St Anne School Ibadan fún ẹ̀kọ́ girama rẹ. O ṣiṣẹ ni Ilé-ẹjọ́ ti kò tíì lọrùn ṣáájú ki wọn to gbàá si Ilé-ẹjọ́ gíga jùlọ. Gbígbàá sí ilé-ẹjọ́ gíga julọ yìí, pẹlu ti John Fabiyi, wáyé nipasẹ Ààrẹ Umaru Musa Yar'Adua ni ọjọ́ kẹfà Oṣu Kẹta ọdún 2009. [3]
Ni ọdún 2012 Onídàájọ Adekeye sàlàyé pé “kíkọ àwọn ìdájọ kii ṣe fun awọn onidajọ ọ̀lẹ.” O ti fẹ̀yìntì lati ibùjókòó ilé-ẹjọ́ giga jùlọ ni Oṣù kọkànlá ọdún 2012. Ninu ọrọ kan ti o sọ ni apejọ ile-ẹjọ valedictory, o pe fun atunyẹwo awọn eto ìmúlò ti o dina àwọn obìnrin ti n bẹ nílé ọkọ lati de ipo gíga ti iṣẹ wọn ni ìlú abinibi ọkọ wọn: [4] “Àwọn ẹ̀dùn ọkàn irú èyí ti pọ̀ jùlọ ní báyìí. Ọ̀pọ̀ obìnrin máa ń yí àyè iṣẹ́ wọn padà sí ìpínlẹ̀ ọkọ wọn lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ lẹ́yìn ìgbéyàwó. Èyí ló ní ìtòótọ́, ó sì fara mọ́ ìlànà ìgbéyàwó pé ọkọ àti ìyàwó yóò di ọ̀kan ṣoṣo. Nínú díẹ̀ lára àwọn àṣà ìbílẹ̀, pàápàá jùlọ lára Yorùbá, ìyàwó kò ní ipò mọ́ nílé bàbá rẹ̀ lẹ́yìn ìgbéyàwó. Nígbà gbogbo tí àyè iṣẹ́ ọ̀gá ba ṣí sílẹ̀ ni ìpínlẹ̀ ọkọ rẹ̀, a máa kọ́ ọ́ ipò náà fún nítorí kó jẹ́ ọmọ ìbílẹ̀ ibẹ̀, wọ́n á sì tún rán án padà sí ìpínlẹ̀ ìbí rẹ̀, lẹ́yìn tí ó ti dé ipò gíga lénu iṣẹ́ náà àti pé ó ti fi ọ̀pọ̀ ọdún sílẹ̀ nínú iṣẹ́ náà.[5]
- ↑ https://allafrica.com/stories/201603220290.html
- ↑ https://www.thisdaylive.com/index.php/2019/01/06/after-a-hard-won-battle-abba-aji-set-to-become-nigerias-7th-female-scourt-justice/
- ↑ https://allafrica.com/stories/200903090799.html
- ↑ Controversy Mars Swearing In of Appeal Court Justice[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]2012.https://scannewsnigeria.com/featured-post/controversy-mars-swearing-in-of-appeal-court-justice-2/
- ↑ https://www.researchgate.net/publication/286457836_BREAKING_THE_YOKE_OF_PATRIARCHY_NIGERIAN_WOMEN_IN_THE_VARIOUS_PROFESSIONS_POLITICS_AND_GOVERNANCE_1914-2014