Jump to content

Olusegun Olusola

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Short description|Nigerian television producer (1935–2012)}}

Olusegun Olusola
Ọjọ́ìbí18 March 1935
Iperu Remo, Ogun State, Nigeria
Aláìsí21 June 2012(2012-06-21) (ọmọ ọdún 77)
Iṣẹ́
  • diplomat
  • television producer
  • director
  • broadcaster
Ìgbà iṣẹ́19552012
Notable workThe Village Headmaster

Chief Olusegun "Segun" Olusola LL-Q34311 (yor)-Tunmise123-Olusegun Olusola.wav Listen(Ṣẹgun Oluṣọla; 18 March 1935 – 21 June 2012) jẹ́ ọmọ ilẹ̀ Nàìjíríà tí ó ń ṣíṣe gẹ́gẹ́ bí adarí èrò àgbéléwò tẹlifíṣontelevision producer,tí ilé ìṣe broadcaster and diplomat.[1] Òun ni ónkowe àti olùdarí executive producer fún ìwé The Village Headmaster,“Eré tẹlifíṣọ̀nù pẹ̀lú ìtàn àtẹ̀jáde tó ti pé jù lọ ní Nàìjíríà tí ó ní tí ó mú ọ̀gbẹ́ni Justus Esiri àti Femi Robinson di irawo àjítaná wò.[2][3]

Ìgbà Ìkókó Ìgbé Ayé

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Olóyè Olusola ìlú Iperu ni Remo , ìlú kan ní Ipinlẹ̀ Ogun, ní apá Gúúsù ìwọ̀-oòrùn Nàìjíríà . Ó lọ sí Remo Secondary School, Sagamu, níbi tí ó ti gba West African Senior School Certificate rẹ̀ ní ọdún 1947 kí ó tó lọ sí University of Pittsburgh, ní Pittsburgh, níbi tí ó ti gba ìyẹ́rìí bachelor's degree rẹ̀.[4]


Ó padà sí ìlú Nàìjíríà ni ọdún 1955 láti darapọ̀ mó mọ́ iṣẹ́ Federal Radio Corporation of Nigeria (FRCN) gẹ́gẹ́ bí Ọ́físa Ìkede (Broadcasting Officer).[5] Lẹ́yìn tí ni ó kúrò ní FRCN ni ọdún 1959 ni ó darapò mo ilé isẹ́ telefíṣọ́n àgbéléwò tí Nigerian Television Authority, níbi ti o ti dìde gba ipò adarí eto ètò executive producer ni ọdún 1964, ní ọdún kaná, ní ó kó The Village Headmaster.[6] Ní ìgbà tí ó di ọdún 1973, Ó di igbákejì alága tí Broadcasting Organisation of Nigeria's Planning Committee fún gbogbo ilé Adúláwò ìyẹn Second All African Games .[7] Ní ọdún 1965, ó di olùdarí gbogbo ètò tí ó wà lábẹ́ ilé iṣẹ́ tẹlifíṣọ̀n àgbéléwò ìyẹn tí Nigerian Broadcasting Commission. Ó jé olùdarí náà fún ọdún mẹ́sàn-án kí ó tó di wípé wọn yàn sì ipò olùdarí ètò ni ilé ìṣe telefíṣọ̀n tí NTA tí ìlú Èkó ni ọdún 1974, ó sì wá lórí ipò yìí fún ọdún méjì, kí ó tó di aláṣẹ olùdarí ni ọdún 1976. Ní ọdún 1978 wọn yàn gẹ́gẹ́ bíi ọ̀gá pátápátá tí ó sì lọ ipò náà fún ọdún mẹ́san-àn. [8][9] Ní ọdún 1987, General Ibrahim Babangida, the former military head of state yàn gẹ́gẹ́ bíi aṣojú fún Ethiopia pẹ̀lú Organisation of African Unity .[10] Olusola died on 21 June 2012 at the age of 77 after a brief illness.[11]

Àwọn ìwé tí ó ko

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ó ti ṣagbátẹrù ìwé tí ó pò lọ́pọ́lọ́pọ̀ lára wọn ni The Village Headmaster (1977), Some Notes on 20 Years of Television in Nigeria (1979), Performing Arts, Broadcasting, Culture and National Development (2004), and Footprints in the Sands of Time (2005).[12][13][14] In addition, he was cited by peers and several others and in 2002, Akin Iroko wrote a book that centred on his biography.[15][16]

  1. "Ambassador Olusegun Olusola, Broadcaster, Diplomat, Takes Final Bow, Articles | THISDAY LIVE". www.thisdaylive.com. Archived from the original on 2012-06-23. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "Village headmaster, Femi Robinson dies at 75". Punch News. Archived from the original on 24 May 2015. Retrieved 23 May 2015. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. Victor Akande, "‘Village Headmaster’ Esiri dies at 70", The Nation, 21 February 2013.
  4. "Village Headmaster Creator, Amb Segun Olusola is dead", Vanguard, 21 June 2012.
  5. "Remembering Segun Olusola", The Nation, 20 October 2013.
  6. "The Village Headmaster returns". Archived from the original on 2015-05-24. Retrieved 2015-05-24. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  7. "Ambassador Segun Olusola is dead", Channels Television, 22 June 2012.
  8. "Family, friends bid Ambassador Segun Olusola farewell — The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper". Archived from the original on 2012-07-23. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  9. "Ambassador Olusegun Olusola Buried"[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́], Nigeria Daily News, 20 July 2012.
  10. "Drama as Ambassador Segun Olusola is buried", Premium Times,
  11. "Ambassador Segun Olusola, Creator Of "Village Headmaster", Dies At 77", Sahara Reporters, 21 June 2012.
  12. "Chief Segun Olusola", Open Library.
  13. Segun Olusola, "Performing arts, broadcasting, culture and national development: a report card", National Gallery of Art of Nigeria, 2004.
  14. Ṣẹgun Oluṣọla, Oladipo Duyile-Ibironke, "Chief Segun Olusola: Footprints in the Sands of Time", Potter's House, 2005.
  15. "Segun Olusola : the real village headmaster".
  16. Akin Iroko, "Segun Olusola: The Real Village Headmaster", Concept Publications, 2002.