Jump to content

Oluwayomi Oluwapelumi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Fáìlì:Picture of Oluwayomi Oluwapelumi.jpg
Àwòrán Oluwayomi Oluwapelumi

Oluwayomi Oluwapelumi jẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́, akọ̀ròyìn, ajàfẹ́tọ̀ọ́ àwọn ọ̀dọ́ àti olùdarí agbègbè ìbílẹ̀, ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Òun ni olóòtú kejì fún ètò Sunday Show lórí NTA.[1]

Ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè B.Sc. nínú ìmọ̀ Mass Communication, láti National Open University of Nigeria, bẹ́ẹ̀ sì ni ó gboyè Diploma nínú ìmọ̀ Mass Communication bákan náà, láti Nigerian Institute of Journalism. Yàtọ̀ sí èyí, ó gba ìwé-ẹ̀rí gẹ́gẹ́ bí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ nínú ìmọ̀ kíkọ ìròyìn láti Nigerian Broadcast Academy.[2]

Oluwapelumi ni olùdásílẹ̀ Sconcerns Media Network and Magazines Ltd & Recordbreaker Global Ventures. Ní ọdún 2024, ó darí ìfẹ̀hónúhàn kan láti dẹ́kun ìtàjẹsílè àwọn òṣìṣẹ́ tó ń rí sí ìdáàbòbò.[3] Ní ọdún 2022, ó gba àmì-ẹ̀yẹ lọ́wọ́ Lions Club fún iṣẹ́ ribiribi rẹ̀.[4]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. Oluwayemi, Oluwapelumi (2024-04-25). "Breaking News, Nigerian News, Paris2024, EndBadGovernanceInNigeria, Protest & Top Stories". PMNews Nigeria. Retrieved 2025-05-21.
  2. Online, ClipTv (2025-01-25). "International Day of Education: Amb. Oluwapelumi Urges Reforms and Community Development". ClipTv Online. Archived from the original on 2025-02-14. Retrieved 2025-05-21.
  3. https://thenationonlineng.net/group-seeks-end-to-attacks-on-security-personnel/
  4. https://theeagle.com.ng/topic/lion-oluwayomi-oluwapelumi-jegede-and-other-recognised-dignitaries-during-the-charter-presentation-and-installation-of-other-club-officers-on-june-11th/