Omoowa Omoregie
Ìrísí
| Òrọ̀ ẹni | ||||||||||||||
|---|---|---|---|---|---|---|---|---|---|---|---|---|---|---|
| Orúkọ kíkúnrẹ́rẹ́ | Omoowa Omoregie | |||||||||||||
| Ọmọorílẹ̀-èdè | ||||||||||||||
| Ọjọ́ìbí | Nigeria | |||||||||||||
| Sport | ||||||||||||||
| Erẹ́ìdárayá | Taekwondo | |||||||||||||
| Event(s) | 53 kg | |||||||||||||
Iye ẹ̀ṣọ́
| ||||||||||||||
Omoowa Omoregiejẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kan tó ń ṣe eré taekwondo tó ń díje nínú ẹ̀ka àwọn obìnrin tó jẹ́ ọmọ ọdún 2009. Ó gba ẹ̀bùn idẹ ní ìdíje Taekwondo ti Áfíríkà ní ẹ̀ka –metalelàádọ́ta kg.
Iṣẹ́ eré ìdárayá
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Omoregie kópa nínú ìdíje metalelàádọ́ta kg ní ìdíje Taekwondo Africa ti ọdún 2009 tí ó wáyé ní Yaoundé, nígbà tí ó dé ipò kẹta, ó gba àmì ẹ̀yẹ idẹ. [1]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "TaekwondoData". TaekwondoData (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-05-22.