Opeyemi Oke
Opeyemi Olufunmilayo Oke | |
|---|---|
| Chief Judge of Lagos State | |
| In office 25 September 2017 – 10 June 2019 | |
| Asíwájú | Oluwafunmilayo Olajumoke Atilade |
| Arọ́pò | Kazeem Alogba |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 10 Oṣù Kẹfà 1954 |
Opeyemi Olufunmilayo Oke (a bí ní ọjọ́ kẹwa oṣù kẹfà ọdún 1954) jẹ ọmọ orilẹ-ède Nàìjíríà àti adájọ àgbà tẹ́lẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Eko . Gómìnà Akinwunmi Ambode ló yán an ni oṣù kẹ̀sán ọdún 2017 gẹgẹ bí adájọ àgbà kẹrindínlógún ìpínlẹ̀ náà.
Ìbẹrẹ Ìgbésí ayé àti ẹkọ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]A bí láti ọdọ àwọn òbí rẹ lati ipinlẹ Ogun, Oke kọ ẹkọ alákọ́bẹ̀rẹ̀ rẹ lati Methodist Primary School ni Surelere àti Methodist Primary School, Ekotẹ̀dó Ibadan. O tẹsiwaju nínú ẹkọ gírámà rẹ ni ilè ìwé awọn ọga Fásítì ilè Ìfẹ ti o wà ni Ibadan, kó tó lọ sí Fiwasaiye Anglican Girls' Grammar School, Akure. Lẹyìn náà o wà pari ẹkọ rẹ ni Olivet Baptist High School, Oyo. Oke jẹ ọmọ ilè ìwé giga Yunifasiti ti Ife . Láàrin ọdún 1978 ati ọdún 1979, o lọ si ile-iwe ofin Naijiria . Lẹhinna o gbá ìwé ẹ̀rí ìyẹ̀wù kejì nínú idajọ ọdaràn lati Coppin State College, Baltimore. [1]
Iṣẹ-ṣiṣe
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Wọn yán Oke gẹgẹ bi adájọ àgbà lẹyìn ti Oluwafunmilayo Olajumoke Atilade ti fẹyinti. Lẹhinna wọn fi idi rẹ mulẹ nipasẹ Apejọ Eko, akọkọ ni agbara iṣe ṣaaju ki o to yan ni pataki ni Oṣu Kẹwa ọdun 2017. [2] [3] [4]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ https://thenigerialawyer.com/profile-of-justice-opeyemi-oke-lagos-in-coming-acting-chief-judge/[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
- ↑ https://www.lagoshouseofassembly.gov.ng/2017/10/19/lagos-assembly-confirms-ambode-s-chief-justice-nominee-chief-judge-charges-governors-on-death-warrants/[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
- ↑ http://saharareporters.com/2017/10/20/ambode-swears-justice-oke-new-chief-judge-lagos
- ↑ https://punchng.com/justice-opeyemi-oke-becomes-lagos-acting-chief-judge/