Jump to content

Orisa Oluwa

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Òrìsà Olúwa jẹ́ òrìṣà kan nínú ẹ̀sìn àbáláyé àwọn Yorùbá tí ó ní èèwò lílo agboòrùn (umbrella) ní ìlú Ìwòyè-Kétu, ìlú kan ní ìpínlẹ̀ Ògùn, lápá ìwò-oòrùn Nigeria.[1] Òrìṣà náà jẹ́ ọ̀kan lára àwọn nǹkan mẹ́ta tí Ọba Olómù mú dání láti Ilé-Ifẹ̀. Adè àti òpá-àṣẹ, tí wọ́n ń pè ní Òpá Ogbó ni àwọn nǹkan tí ó mú ṣìkejì àti kẹta wá sí ìlú náà lásìkò náà.[2]

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Iwoye-Ketu: Town on the Nigeria-Benin border where Umbrella is forbidden". The Sun News. Retrieved July 24, 2015.
  2. "Ogun monarch laments neglect of Iwoye border". The Punch News. Archived from the original on July 24, 2015. Retrieved July 24, 2015. Unknown parameter |url-status= ignored (help)