Orisa Oluwa
Ìrísí
Òrìsà Olúwa jẹ́ òrìṣà kan nínú ẹ̀sìn àbáláyé àwọn Yorùbá tí ó ní èèwò lílo agboòrùn (umbrella) ní ìlú Ìwòyè-Kétu, ìlú kan ní ìpínlẹ̀ Ògùn, lápá ìwò-oòrùn Nigeria.[1] Òrìṣà náà jẹ́ ọ̀kan lára àwọn nǹkan mẹ́ta tí Ọba Olómù mú dání láti Ilé-Ifẹ̀. Adè àti òpá-àṣẹ, tí wọ́n ń pè ní Òpá Ogbó ni àwọn nǹkan tí ó mú ṣìkejì àti kẹta wá sí ìlú náà lásìkò náà.[2]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Iwoye-Ketu: Town on the Nigeria-Benin border where Umbrella is forbidden". The Sun News. Retrieved July 24, 2015.
- ↑
"Ogun monarch laments neglect of Iwoye border". The Punch News. Archived from the original on July 24, 2015. Retrieved July 24, 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help)