Tóyìn Abraham: Ìyàtọ̀ láàrin àwọn àtúnyẹ̀wò

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Content deleted Content added
No edit summary
Àwọn àlẹ̀mọ́: Àtúnṣe ojú fóónù Àtúnṣe ojú fóónù Advanced mobile edit
se afikun eka
Ìlà 54: Ìlà 54:
[[Ẹ̀ka:Àwọn ènìyàn alààyè]]
[[Ẹ̀ka:Àwọn ènìyàn alààyè]]
[[Ẹ̀ka:Àwọn ọjọ́ìbí ní 1984]]
[[Ẹ̀ka:Àwọn ọjọ́ìbí ní 1984]]
[[Ẹ̀ka:21st-century Nigerian actresses]]

Àtúnyẹ̀wò ní 23:53, 19 Oṣù Kẹ̀wá 2020

Toyin Abraham
Toyin Abraham at AMVCA 2020
Ọjọ́ìbí5 Oṣù Kẹ̀sán 1980 (1980-09-05) (ọmọ ọdún 43)
Auchi, Edo, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
  • actress
  • filmmaker
  • producer
  • director
Ìgbà iṣẹ́2003–present

Toyin Abraham[1] tàbí Olutoyin Aimakhu; ni wọ́n bí ní (September 5, 1984). Ó jẹ́ is a Nigerian òṣèré orí ìtàgé , olùgbéré-jáde àti adarí eré, ọmọ rílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[2][3]

Ìbẹ̀rẹ̀ ìgbésí ayé àti ẹ̀kọ́ rẹ̀

Wọ́n bi ní ìlú Auchi, tí ó jẹẹ́ ìlú kan ní town in ìpínlẹ̀ Ẹdó ní orílẹ̀-èdẹ Nàìjírìà. Àmọ́ ṣá, ó bẹ̀rẹ̀ ayé rẹ̀ ní ìlú Ìbàdàn, tí ó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìwọ̀ Oòrùn ilẹ̀ Nàìjíríà.[4] Ó gba ìwé ẹ̀rí HND (Higher National Diploma) ní ilé-ẹ̀kọ́ gbogbo-nìṣe ìlú Ìbàdàn ìyẹn (Ibadan Polytechnic), lásìkọ́ yí, ó jẹ́ akẹgbẹ́ pẹ̀lú Dibie, C.B.N aka x7,[5] Tóyìn Abraham ti fara hàn nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ eré, tí ó sì tún ṣẹ̀ṣẹ̀ kópa nínú sinimá àgbéléwò aré tí orúkọ̀ rẹ̀ ń jẹ́ Black Val.[6]

Iṣẹ́ rẹ̀

Tóyìn bẹ̀rẹ̀ eré orí ìtàgé rẹ̀ nígbà tí gbajú-gbajà òṣèré orí-ìtàgé tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Bukky Wright, wá sí ìlú Ìbàdàn láti yàwòrán eré kan .[7] Ó ti darí, kópa àti gbé eré jáde fúnra rẹ̀, lára rẹ̀ ni Àlání Bàba Làbákẹ́ àti d Èmi ni[8]. Wọ́n yàán gẹ́gẹ́ bí òṣèré amúgbá-lẹ́gbẹ̀ẹ́ obìnrin tó dára jùlọ (Best Supporting Actress) nínú eré orí ìtàgé tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ "Ẹ̀bi mi ni" nínú àmì ẹ̀yẹ 2013 Best of Nollywood Awards , bákan náà ni wọ́n yan Jọkẹ́ Múyìwá fún Best Lead Actress nínú eré tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ Ayítakẹ̀.[9] Ẹ̀wẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn olóṣèlú ló ti pèé láti bá wọn polongo ètò ìdìbò fún Ààrẹ ilẹ̀ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ tí ó jẹ́ adíje dupò sí orí àpèrè Ààrẹ ìyẹn Goidluck Ebele Jonathan ní ọdún 2015. Tóyìn pàá pàà só wípé òun lè kú torí ẹgbẹ́ òṣèlú Oeopel Democratic Party (PDP) kú[10] tí ó jẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú tí adíje dupò náà ti ń díje. Àmọ́ ṣá, ó padà yí gbólóhùn rẹ̀ padà wípé òun bẹ àwọn olólùfẹ́ òun wípé kí ẹnikẹ́ni ó má ṣe ta ẹ̀jẹ̀ ẹnikẹni sílẹ̀ lásìkò ìdìbò.[11]

Àwọn eré ìtàgé rẹ̀

  • Okafor's Law (2016)
  • Love is in the Hair (2016)
  • Àlàní Bàbá Làbákẹ́ (2013)
  • Ẹ̀bi mi ni (2013)
  • Alákadá (2013)
  • Ṣọlá fẹ́ pa mí
  • Ghost and the tout (2018)

Ẹ tún le wo

  • List of Nigerian film producers

Àwọn ìtọ́ka sí

  1. "Nollywood Star, Aimakhu Now To Be Called Toyin Abraham". Channels Television. https://www.channelstv.com/2016/12/29/nollywood-star-aimakhu-now-to-be-called-toyin-abraham/. Retrieved 30 December 2016. 
  2. Empty citation (help) 
  3. Empty citation (help) 
  4. Empty citation (help) 
  5. Empty citation (help) 
  6. Empty citation (help) 
  7. Empty citation (help) 
  8. Empty citation (help) 
  9. Empty citation (help) 
  10. "I am ready to die for PDP-Toyin Aimakhu". Gistmaster. http://niyitabiti.net/2015/03/i-am-ready-to-die-for-pdp-toyin-aimakhu/. Retrieved 2018-01-03. 
  11. Empty citation (help) 

Àwọn ìjásóde

  • Toyin Abraham on IMDb