Jump to content

Premium Times

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Premium Times
PTlogonigeria.png
Premium Times logo
TypeOnline newspaper
PublisherDapo Olorunyomi
Editor-in-chiefMusikilu Mojeed
Managing editorsIdris Akinbajo
Founded2011; ọdún 14 sẹ́yìn (2011)
Language
  • English
  • Hausa
HeadquartersAbuja, Nigeria
Official websitepremiumtimesng.com

Premium Times jẹ́ ìwé ìròyìn orí Íńténetì tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe tí ó wà ní ìlú Àbújá, olú-ìlú Nàìjíríà. Wọ́n ṣe ìdásílẹ̀ ìwé ìròyìn náà ní ọdún 2011. [1] Ìròyìn ayélujára máa ń gbìyànjú láti tú àwọn ọ̀rọ̀ tó pamọ́ sí ìta, ní pàtàkì àwọn tí àwọn èèyàn tó wà nípò àṣẹ kò fẹ́ kí ó jáde.

ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pelu Business Day newspaper

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní oṣù kẹsàn-án, ọdún 2023, ìwé ìròyìn orí Íńténetì, Premium Times kéde pé wọ́n ti ṣe ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú Ìwé Ìròyìn Business Day. Wọ́n darapọ̀ mọ́ra láti mú ìròyìn tó dára sí i wá fún àwọn ènìyàn. Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ yìí wá pẹ̀lú èrò láti gbé iṣẹ́ oníròyìn ga ní Nàìjíríà.

  • Ti a yan fún àmì-ẹ̀yẹ “Website/búlọ́ọ̀gì ọdún” ní ibi Àmì-Ẹ̀yẹ Àwọn Olùgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Nàìjíríà ni 2013[2]
  • Ẹ̀bùn Pulitzer fún ipa ti wọ́n kó nínú àwùjọ àwọn oníròyìn káríayé tí wọ́n ṣe ìwádìí lórí Panama Papers, tí ó fi àwọn ìwà ìbàjẹ́ àti àwọn ibi ìpamọ́-owó àṣírí hàn tí àwọn ènìyàn pàtàkì kan lò (2017). .[3]
  • Àmì-ẹ̀yẹ Global Shining Light Award fún iṣẹ́ ìwádìí lórí pípa àwọn ènìyàn láìṣe òfin ní gúúsù-ìlà-oòrùn Nàìjíríà àti bí wọ́n ṣe ṣètò ìpakúpa àwọn tó ń tìlẹyìn fún Biafra ní ìlú Onitsha (2017). [4]
  • Ìdánilólá pẹ̀lu àmì-ẹ̀ye àti ìyìn láti ọ̀dọ̀ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó fún ìròyìn tó jẹ́ mọ́ akọ àti abo (2023). [5]
  1. "About Us". Premium Times. Retrieved 22 April 2018. 
  2. "Here are the Nominees for Nigerian Broadcasters Merit Awards 2013". Olori Supergal (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 31 October 2013. Retrieved 11 April 2018. 
  3. Digit, Control (11 April 2017). "'Fake News' reporters win Pulitzer awards". Business Day Newspaper. Business Day Newspaper. Archived from the original on 24 May 2018. https://web.archive.org/web/20180524152215/http://www.businessdayonline.com/fake-news-reporters-win-pulitzer-awards/. 
  4. GIJN, Staff (18 November 2017). "Investigative Stories from Iraq, Nigeria Win Global Shining Light Award". Global Investigative Journalism Network. Retrieved 24 May 2018. 
  5. Stephen, Onu (30 September 2023). "PREMIUM TIMES wins Lagos State Governor’s award". Premium Times Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2 October 2023.