Premium Times
Ìrísí
| PTlogonigeria.png Premium Times logo | |
| Type | Online newspaper |
|---|---|
| Publisher | Dapo Olorunyomi |
| Editor-in-chief | Musikilu Mojeed |
| Managing editors | Idris Akinbajo |
| Founded | 2011 |
| Language |
|
| Headquarters | Abuja, Nigeria |
| Official website | premiumtimesng.com |
Premium Times jẹ́ ìwé ìròyìn orí Íńténetì tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe tí ó wà ní ìlú Àbújá, olú-ìlú Nàìjíríà. Wọ́n ṣe ìdásílẹ̀ ìwé ìròyìn náà ní ọdún 2011. [1] Ìròyìn ayélujára máa ń gbìyànjú láti tú àwọn ọ̀rọ̀ tó pamọ́ sí ìta, ní pàtàkì àwọn tí àwọn èèyàn tó wà nípò àṣẹ kò fẹ́ kí ó jáde.
ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pelu Business Day newspaper
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ní oṣù kẹsàn-án, ọdún 2023, ìwé ìròyìn orí Íńténetì, Premium Times kéde pé wọ́n ti ṣe ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú Ìwé Ìròyìn Business Day. Wọ́n darapọ̀ mọ́ra láti mú ìròyìn tó dára sí i wá fún àwọn ènìyàn. Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ yìí wá pẹ̀lú èrò láti gbé iṣẹ́ oníròyìn ga ní Nàìjíríà.
Àwọn Ìdánimó
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Ti a yan fún àmì-ẹ̀yẹ “Website/búlọ́ọ̀gì ọdún” ní ibi Àmì-Ẹ̀yẹ Àwọn Olùgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Nàìjíríà ni 2013[2]
- Ẹ̀bùn Pulitzer fún ipa ti wọ́n kó nínú àwùjọ àwọn oníròyìn káríayé tí wọ́n ṣe ìwádìí lórí Panama Papers, tí ó fi àwọn ìwà ìbàjẹ́ àti àwọn ibi ìpamọ́-owó àṣírí hàn tí àwọn ènìyàn pàtàkì kan lò (2017). .[3]
- Àmì-ẹ̀yẹ Global Shining Light Award fún iṣẹ́ ìwádìí lórí pípa àwọn ènìyàn láìṣe òfin ní gúúsù-ìlà-oòrùn Nàìjíríà àti bí wọ́n ṣe ṣètò ìpakúpa àwọn tó ń tìlẹyìn fún Biafra ní ìlú Onitsha (2017). [4]
- Ìdánilólá pẹ̀lu àmì-ẹ̀ye àti ìyìn láti ọ̀dọ̀ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó fún ìròyìn tó jẹ́ mọ́ akọ àti abo (2023). [5]
Àwon Ítokási
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "About Us". Premium Times. Retrieved 22 April 2018.
- ↑ "Here are the Nominees for Nigerian Broadcasters Merit Awards 2013". Olori Supergal (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 31 October 2013. Retrieved 11 April 2018.
- ↑ Digit, Control (11 April 2017). "'Fake News' reporters win Pulitzer awards". Business Day Newspaper. Business Day Newspaper. Archived from the original on 24 May 2018. https://web.archive.org/web/20180524152215/http://www.businessdayonline.com/fake-news-reporters-win-pulitzer-awards/.
- ↑ GIJN, Staff (18 November 2017). "Investigative Stories from Iraq, Nigeria Win Global Shining Light Award". Global Investigative Journalism Network. Retrieved 24 May 2018.
- ↑ Stephen, Onu (30 September 2023). "PREMIUM TIMES wins Lagos State Governor’s award". Premium Times Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2 October 2023.