Moji Afolayan: Ìyàtọ̀ láàrin àwọn àtúnyẹ̀wò
Content deleted Content added
No edit summary Àwọn àlẹ̀mọ́: Àtúnṣe ojú fóónù Àtúnṣe ojú fóónù Advanced mobile edit |
Deborahjay (ọ̀rọ̀ | àfikún) Ẹ̀ka; Àdàkọ:Igbesiaye |
||
Ìlà 27: | Ìlà 27: | ||
==Àwọn Ìtọ́kasí== |
==Àwọn Ìtọ́kasí== |
||
{{Reflist}} |
{{Reflist}} |
||
{{Igbesiaye|1969||Afolayan, Moji}} |
|||
[[Ẹ̀ka:Àwọn òṣeré ará Nàìjíríà]] |
Àtúnyẹ̀wò ní 14:21, 25 Oṣù Kẹ̀sán 2020
Mojí Afọláyan | |
---|---|
Ọjọ́ìbí | Ibadan, Oyo, Nigeria | 5 Oṣù Kejì 1969
Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
Ọmọ orílẹ̀-èdè | Nigerian |
Iṣẹ́ |
|
Olólùfẹ́ | Rasaq Olayiwola |
Parent(s) | Ade Love (father) |
Àwọn olùbátan | Kunle Afolayan (brother) Gabriel Afolayan (brother) Aremu Afolayan (brother) |
Mojí Afọláyan tí wọ́n bí ní Ọjọ́ karùn-ún oṣù kejì ọdún 1969 (February 5, 1969) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèrébìnrin, olóòtú àti olùdarí sinimá-àgbéléwò ọmọ bíbí Yorùbá láti ìlú Ìbàdàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1] Mojí jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ bíbí olóògbé òní-sinimá àgbéléwò Adéyẹmí Josiah Afọláyan[2] tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ade Love nígbà ayé rẹ̀. Mojí Afọláyan fẹ́ gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò, Razaq Ọláyíwọlá tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Òjòpagogo. [3]
Àwọn Ìtọ́kasí
- ↑ "Why my husband stays at home to nurse the kids-Moji Afolayan". The Nation Newspaper. Retrieved 27 February 2015.
- ↑ "Dad didn’t encourage his children to act —Kunle Afolayan". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. 2015-02-28. Archived from the original on 2015-02-28. Retrieved 2019-12-31. Unknown parameter
|url-status=
ignored (help) - ↑ "Latest Nigeria news update". The Nation Newspaper (in Èdè Latini). 2018-09-03. Retrieved 2019-12-31.