Jump to content

Rasheed Ijaodola

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Rasheed Lawal Jimoh Ijaodola jẹ oṣiṣẹ amofin ọmọ orilẹ-ede Nàìjíríà ti o ṣe kẹ́kọ̀ọ́ nípa ìwé òfin orílè-èdè àti awọn ọran ìdìbò. O jẹ Agbẹjọro Agba ti Nàìjíríà (SAN) ati ọmọ ẹgbẹ ti Nigerian Bar Association, Ẹka Ilorin, títí o fi kú. [1] [2] [3]

Igbesi aye ibẹrẹ ati ẹkọ

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ijaodola je ọmọ bíbí ìlù Offa ni ijoba ibile Offa ni ipinle Kwara . Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ́ Kátólíìkì ní Gánà, ó sì gba ìwé ẹ̀rí àkọ́kọ́ àti MSc nínú òfin láti Yunifásítì ti Èkó pẹ̀lú oyè PhD nínú Ẹ̀kọ́ Kristẹni àti àwọn ìwé ẹ̀rí mẹ́ta mìíràn, bó tilẹ̀ jẹ́ pé Mùsùlùmí ni. [4] [5]

Wọ́n pe Ijaodola lọ sí ọgbà ní ọjọ́ 30, oṣù keje, ọdún 1984.

Ṣáájú ikú rẹ Ijaodola jẹ oga àgbà Ẹ̀ka òfin, ní ilé ìwé ẹkọ gíga Igbinedion University, Okada, ni Ìpínlẹ̀ Edo ni orílè-èdè Nàìjíríà o tí fi gbà kàn jẹ olùkọ́ni nípa òfin ni University ti Ilorin . [6]

  1. https://thenationonlineng.net/kwara-governor-mourns-ijaodola/
  2. https://thenationonlineng.net/zoning-presidential-office-not-democratic/amp/
  3. https://kblsp.org.ng/index.php/kblsp/about/editorialTeam
  4. https://dailytrust.com/i-was-denied-employment-for-being-muslim-muslim-phd-holder-in-christian-studies/
  5. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2025-07-10. Retrieved 2025-07-08. 
  6. Empty citation (help)