Jump to content

Richard Oguntimehin

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Richard Oguntimehin tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Don Richard (tí wọ́n bí 18th May 1975[1]) jẹ́ òṣèré sinimá àgbéléwò ọmọ Ìpínlẹ̀ Ondo lórílẹ̀-èdè Nigeria.[2]

Wọ́n bí Richard ní ìlú Ondo, lápá ìwọ̀n oòrùn lórílẹ̀- èdè Nigeria. Ó bẹ̀rẹ̀ ẹ̀kọ́ ní ilé-ìwé Lady Lark Primary School ní Bàrígà ní ìlú Èkó, ó tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní ilé-ìwé gíga ní Baptist Academy ní ìlú Èkó bákan náà. Ó kàwé gboyẹ̀ dìgírì àkọ́kọ́ nínú ìmọ̀ Ètò-ọrọ̀ ajé (Economic) ní ilé-ẹ̀kọ́ Ifáfitì Abia State University, bẹ́ẹ̀ náà ló gbà dìgírì kejì, (Masters) ní University of Lagos

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Richard Oguntimehin Biography: Age, Family, Spouse, Career, Net Worth 2025". GospelTunes. 2025-07-31. Retrieved 2025-10-27.
  2. Medeme, Ovwe (2025-07-30). "Veteran actor Don Richard opens up on kidney disease diagnosis, seeks N50 million lifeline". Premium Times Nigeria. Retrieved 2025-10-27.