Rifkatu Adamu Chidawa
Rifkatu Adamu Chidawa | |
|---|---|
| Ministry of Tourism and Culture (Niger State) | |
| Gómìnà | Sani Bello |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | Niger State |
| Education | |
Rifkatu Adamu Chidawa (tí a bí ní ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kejì ọdún 1956) ó jẹ́ alábòójútó-àgbà fún àwọn arìnrìn-àjò àti àṣà ní ìpínlẹ̀ Náíjáà, ní Orílè-èdè Nàìjíríà láti 2019 sí 2023.[1][2][3]
Iṣẹ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Chidawa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ṣíṣe gẹgẹ́ bí olùkọ́. Ó jé Ádárì oríṣiríṣi ilé ẹ̀kọ́ Gírámà ni Ìpínlẹ̀ Abuja àti ní Niger.[1] Later on, she was appointed as Commissioner of Tourism and Culture.[1] O sì bẹ̀rẹ̀ Ètò láti má ṣe àyẹ̀wò fún Àrùn Jẹjẹrẹ (Cancer) ni agbègbè Gurara ni ìpínlẹ̀ Niger.[4]
Ètò Ẹ̀kọ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ó bẹ̀rẹ̀ ilé ìwé alákọ̀bẹrẹ̀ ni osu kinni ọdún 1962, leyin ti ó lọ sí ilé ìwé ìjọba tí wọ́n dà sílé fún àwọn obìnrin ní Minna. Ó kàwé gboyè NCE [National Certificate of Education]] ni ọdún 1981. Chidawa lọ sìn ijoba gẹ́gẹ́ ni agùnbánirọ̀ fún ọdún kan ni Ilé ìwé gírámà tí ìjọba dà sílé fún ọdún ní ọdún 1981.Àdàkọ:Clarify Ó kẹ́kọ̀ọ́ nípa Ètò Ẹ̀kọ́, ó sì gboyè àkọ́kọ́ B.Ed láti Fáṣítì Ahmadu Bello lórí Eto Ẹ̀kọ́. Lèyín èyí ni ó tẹ̀síwájú láti tún bọ́ kàwé ni Fáṣítì tí ó wà ní Abuja ni ọdún 1999 láti gboyè master nínú Ìṣàkóso Ẹ̀kọ́ àti Títo Ẹ̀kọ́ (education administration and planning.)[1]
Ìbẹ̀rẹ̀pẹ́pẹ́ Ayé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Wọn bí Chidawa ni Ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kejì ọdún 1956 ni Diko ni Àgbègbè Guara ní Ìpínlẹ̀ Niger, orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.[1]
Ìgbé Ayé ẹ̀ẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ó ti ṣèyàwó, ó sì ti bímọ.[1]
Ẹ tún lè wọ àwọn ìlà wọ̀nyí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- https://mculture.nigerstate.gov. Archived 2020-11-27 at the Wayback Machine. ng
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 1 2 3 4 5 6 Chukwudiebere, Mercy (2019-10-31). "Twenty Commissioners join Niger State Executive Council". Voice of Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2019-11-01. Retrieved 2020-11-19.
- ↑ Minna, Romoke W. Ahmad (2020-06-29). "Niger targets increased IGR from tourism". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2020-11-27. Retrieved 2020-11-19.
- ↑ Admins (2019-10-30). "'No first-class commissioners' in my cabinet, says Sani-Bello". Newsdiaryonline Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-11-19.
- ↑ Asishana, Justina (2020-10-26). "Rural Women In Gurara Receive Free Cancer Screening". Transcontinental Times (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-11-19.