Jump to content

Rifkatu Adamu Chidawa

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Rifkatu Adamu Chidawa
Ministry of Tourism and Culture (Niger State)
GómìnàSani Bello
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbíNiger State
Education

Rifkatu Adamu Chidawa (tí a bí ní ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kejì ọdún 1956) ó jẹ́ alábòójútó-àgbà fún àwọn arìnrìn-àjò àti àṣà ní ìpínlẹ̀ Náíjáà, ní Orílè-èdè Nàìjíríà láti 2019 sí 2023.[1][2][3]

Chidawa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ṣíṣe gẹgẹ́ bí olùkọ́. Ó jé Ádárì oríṣiríṣi ilé ẹ̀kọ́ Gírámà ni Ìpínlẹ̀ Abuja àti ní Niger.[1] Later on, she was appointed as Commissioner of Tourism and Culture.[1] O sì bẹ̀rẹ̀ Ètò láti má ṣe àyẹ̀wò fún Àrùn Jẹjẹrẹ (Cancer) ni agbègbè Gurara ni ìpínlẹ̀ Niger.[4]

Ó bẹ̀rẹ̀ ilé ìwé alákọ̀bẹrẹ̀ ni osu kinni ọdún 1962, leyin ti ó lọ sí ilé ìwé ìjọba tí wọ́n dà sílé fún àwọn obìnrin ní Minna. Ó kàwé gboyè NCE [National Certificate of Education]] ni ọdún 1981. Chidawa lọ sìn ijoba gẹ́gẹ́ ni agùnbánirọ̀ fún ọdún kan ni Ilé ìwé gírámà tí ìjọba dà sílé fún ọdún ní ọdún 1981.Àdàkọ:Clarify Ó kẹ́kọ̀ọ́ nípa Ètò Ẹ̀kọ́, ó sì gboyè àkọ́kọ́ B.Ed láti Fáṣítì Ahmadu Bello lórí Eto Ẹ̀kọ́. Lèyín èyí ni ó tẹ̀síwájú láti tún bọ́ kàwé ni Fáṣítì tí ó wà ní Abuja ni ọdún 1999 láti gboyè master nínú Ìṣàkóso Ẹ̀kọ́ àti Títo Ẹ̀kọ́ (education administration and planning.)[1]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ́pẹ́ Ayé

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọn bí Chidawa ni Ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kejì ọdún 1956 ni Diko ni Àgbègbè Guara ní Ìpínlẹ̀ Niger, orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.[1]

Ìgbé Ayé ẹ̀ẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ó ti ṣèyàwó, ó sì ti bímọ.[1]

Ẹ tún lè wọ àwọn ìlà wọ̀nyí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. 1 2 3 4 5 6 Chukwudiebere, Mercy (2019-10-31). "Twenty Commissioners join Niger State Executive Council". Voice of Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2019-11-01. Retrieved 2020-11-19.
  2. Minna, Romoke W. Ahmad (2020-06-29). "Niger targets increased IGR from tourism". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2020-11-27. Retrieved 2020-11-19.
  3. Admins (2019-10-30). "'No first-class commissioners' in my cabinet, says Sani-Bello". Newsdiaryonline Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-11-19.
  4. Asishana, Justina (2020-10-26). "Rural Women In Gurara Receive Free Cancer Screening". Transcontinental Times (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-11-19.