Rita Orji (oloselu)
Ìrísí
Rita Orji | |
|---|---|
| Federal Representative | |
| In office 2015–2019 | |
| Constituency | Ajeromi-Ifelodun |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ẹgbẹ́ olóṣèlú | Peoples Democratic Party (Nigeria) (PDP) |
| Occupation | Politician |
Olóṣèlú ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni Rita Orji . Ó jẹ́ ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin tẹ́lẹ̀, ó ń ṣojú fún agbègbè ìjọba àpapọ̀ Ajeromi Ifelodun ní ìpínlẹ̀ Èkó nígbà tí wọ́n ṣe ìpàdé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀-èdè kẹjọ.[1] [2] [3]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Bankole, Idowu (2021-12-29). "It's time to rescue, rebuild Nigeria — Ex-Reps Member, Rita Orji". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-22.
- ↑ "Birthday: Makinde's Ally, Hon Rita Orji Clocks Another Year In Grand Style – Independent Newspaper Nigeria" (in en-GB). Independent (Lagos, Nigeria). 2023-09-26. https://independent.ng/birthday-makindes-ally-hon-rita-orji-clocks-another-year-in-grand-style/.
- ↑ sunnews (2019-04-14). "Ajeromi/Ifelodun-election-Obey-court-order-PDP-Rita-Orji-tell-INEC". The Sun Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-22.