Jump to content

Roseline Sonayee Konya

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Roseline Sonayee Konya
Ọjọ́ìbíKhana, Rivers State
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
Gbajúmọ̀ fúnRivers State Commissioner for Environment
Toxicology and Pharmacology
Notable workSEARCHING THE SOUL OF THE ENVIRONMENT, WHO DARE? TERRITORIANS OR SUBDUERS?

Roseline Sonayee Konya jé olóṣèlú láti Khana, ní ìpínlè Rivers. Ó jẹ ọ̀jọ̀gbọ́n Toxicology and Pharmacology ní ilé ẹ̀kọ́ gíga Port Harcourt.[1][2] ó ṣiṣẹ́ àwọn aláṣẹ fún àyíká[3] ní ilé ìgbìmọ̀ ti Gómìnà Peter Odili wọ́n sì tún yàn sí ipò aláṣẹ ilé ìgbìmọ̀ ti Gómìnà Ezenwo Nyesom Wike.[4] Ó sì tún jẹ́ Alága fún ìgbìmọ̀ iṣẹ́ ìjọba ní ọdún 1997.[5]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Konya Calls For Environmental Stewardship In Nigeria". University of Port Harcourt. Archived from the original on 30 April 2016. Retrieved 17 June 2016. 
  2. Davies Iheamnachor (28 April 2015). "Toxicologists raise alarm over pollutants in N-Delta communities Calls". Vanguard. http://www.vanguardngr.com/2015/04/toxicologists-raise-alarm-over-pollutants-in-n-delta-communities/. Retrieved 17 June 2016. 
  3. "'Government agencies, others fuelling air pollution in Port Harcourt'". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-05-27. Retrieved 2022-04-07. 
  4. John Ighodaro (4 April 2005). "Odili Sets Up Committee to Study Ataba Crisis Report". Vanguard. http://allafrica.com/stories/200504041179.html. Retrieved 17 June 2016. 
  5. "Konya Roseline". LitCaf (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-08-20. Retrieved 2022-03-21.