Jump to content

Sadiya Umar Farouq

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Àdàkọ:Npov

Sadiya Umar Farouq
Minister of Humanitarian Affairs, Disaster Management and Social Development
In office
21 August 2019  29 May 2023
ÀàrẹMuhammadu Buhari
AsíwájúPosition established
Arọ́pòBetta Edu
Federal Commissioner of the National Commission for Refugees, Migrants, and Internally Displaced Persons
In office
September 2016  July 2019
ÀàrẹMuhammadu Buhari
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí5 Oṣù Kọkànlá 1974 (1974-11-05) (ọmọ ọdún 51)
Zurmi, Zamfara State, Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress
EducationAhmadu Bello University
OccupationPolitician

Sadiya Umar Farouq (tí a bí ní ọjọ́ Karùn ún, oṣù kọkànlá ọdún 1974) ó jẹ́ òṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó sì tún jẹ́ aṣáájú òjíṣẹ́ àwọn àjọ-ènìyàn, alábòójútó rògbòdìyàn àwùjọ, àti ìdàgbàsókè àwùjọ.[1][2]

Ààrẹ Muhammadu Buhari ló yàn án ní oṣù keje, ọdún 2019,[3] Farouq ni mínísítà tó kéré jù ní ibi Ìjọba àpapọ̀ nígbà ìjọba Ààrẹ Muhammadu Buhari. Ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí Kọmíṣọ́nà ìjọba àpapọ̀ fún National Commission for Refugees, Migrants, and Internally Displaced Persons láti oṣù kẹwàá ọdún 2016 sí oṣù kẹjọ, ọdún 2019.

Iṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú Ààrẹ Buhari mú wa padà sí ìgbà Buhari gẹ́gẹ́ bí adarí àti Ààrẹ fún Congress for Progressive Change nígbà tí Farouq jẹ́ agbowó àpapọ̀ fún ẹgbẹ́ CPC àti agbowó fún àpapọ̀ fún ẹgbẹ́ All Progressives Congress.[1]

  1. 1 2 "Hajiya "Sadiya Umar Farouq" biography: Buhari youngest cabinet minister profile". BBC News Pidgin. 2019-10-10. https://www.bbc.com/pidgin/tori-50003638.
  2. "FG will address plight of poor, vulnerable Nigerians despite economic challenges – Minister". The Guardian. 2021-10-25. https://guardian.ng/news/fg-will-address-plight-of-poor-vulnerable-nigerians-despite-economic-challenges-minister/.
  3. "Sadiya Farouq: Group lauds Buhari's appointment of Minister". Vanguard. 2020-06-11. https://www.vanguardngr.com/2020/06/sadiya-farouq-group-lauds-buharis-appointment-of-minister/.