Sadiya Umar Farouq
Ìrísí
Sadiya Umar Farouq | |
|---|---|
| Minister of Humanitarian Affairs, Disaster Management and Social Development | |
| In office 21 August 2019 – 29 May 2023 | |
| Ààrẹ | Muhammadu Buhari |
| Asíwájú | Position established |
| Arọ́pò | Betta Edu |
| Federal Commissioner of the National Commission for Refugees, Migrants, and Internally Displaced Persons | |
| In office September 2016 – July 2019 | |
| Ààrẹ | Muhammadu Buhari |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 5 Oṣù Kọkànlá 1974 Zurmi, Zamfara State, Nigeria |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressives Congress |
| Education | Ahmadu Bello University |
| Occupation | Politician |
Sadiya Umar Farouq (tí a bí ní ọjọ́ Karùn ún, oṣù kọkànlá ọdún 1974) ó jẹ́ òṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó sì tún jẹ́ aṣáájú òjíṣẹ́ àwọn àjọ-ènìyàn, alábòójútó rògbòdìyàn àwùjọ, àti ìdàgbàsókè àwùjọ.[1][2]
Ààrẹ Muhammadu Buhari ló yàn án ní oṣù keje, ọdún 2019,[3] Farouq ni mínísítà tó kéré jù ní ibi Ìjọba àpapọ̀ nígbà ìjọba Ààrẹ Muhammadu Buhari. Ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí Kọmíṣọ́nà ìjọba àpapọ̀ fún National Commission for Refugees, Migrants, and Internally Displaced Persons láti oṣù kẹwàá ọdún 2016 sí oṣù kẹjọ, ọdún 2019.
Iṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú Ààrẹ Buhari mú wa padà sí ìgbà Buhari gẹ́gẹ́ bí adarí àti Ààrẹ fún Congress for Progressive Change nígbà tí Farouq jẹ́ agbowó àpapọ̀ fún ẹgbẹ́ CPC àti agbowó fún àpapọ̀ fún ẹgbẹ́ All Progressives Congress.[1]
- 1 2 "Hajiya "Sadiya Umar Farouq" biography: Buhari youngest cabinet minister profile". BBC News Pidgin. 2019-10-10. https://www.bbc.com/pidgin/tori-50003638.
- ↑ "FG will address plight of poor, vulnerable Nigerians despite economic challenges – Minister". The Guardian. 2021-10-25. https://guardian.ng/news/fg-will-address-plight-of-poor-vulnerable-nigerians-despite-economic-challenges-minister/.
- ↑ "Sadiya Farouq: Group lauds Buhari's appointment of Minister". Vanguard. 2020-06-11. https://www.vanguardngr.com/2020/06/sadiya-farouq-group-lauds-buharis-appointment-of-minister/.