Samah Barigou
Ìrísí
| Samah Barigou | |
|---|---|
| Ọmọ orílẹ̀-èdè | Moroko |
| Iṣẹ́ | Òṣèrébìnrin |
| Gbajúmọ̀ fún | Casablanca Beats |
Samah Barigou jẹ́ òṣèrébìnrin ará Mòrókò.[1]Ó jẹ́ olókìkí fún ipa rẹẹ̀ nínu kíkópa rẹ ninu fíìmù Casablanca Beats tí fíìmù na sí jẹ yíyàn lati díje fun Palme d'Or ni Cannes Film Festival ni ọdún 2021.[2][3]
Awọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Samah BARIGOU". Festival de Cannes (in Èdè Faransé). 22 March 2023. Retrieved 6 September 2025.
- ↑ "Haut et fort de Nabil Ayouch (2021)". Unifrance (in Èdè Faransé). 28 October 2022. Retrieved 6 September 2025.
- ↑ Young, Deborah (15 July 2021). "‘Casablanca Beats’: Film Review". The Hollywood Reporter. Retrieved 7 September 2025.