Sani Lulu
Ìrísí
Alhaji Sani Lulu Abdullahi (ọjọ-ibi ọjọ kẹrindínlógún oṣù kẹrin ọdún 1958) jẹ Ààrẹ ẹgbẹ agbábọ́ọlu orílẹ-èdè Naijiria teleri (NFF) . Ṣáájú ki o to di Alákóso NFF ni ọdún 2006, o ti ṣiṣẹ bi olùdarí FCT ti àwọn eré ìdárayá. Ààrẹ NFF rẹ ko pẹ púpọ nítorí ti Ìgbìmọ̀ Alákóso NFF ti yọ ọ kuro ni ọdún 2010. [1] [2] Òun ní Olùdásílẹ̀ ati oludari agba ti Fosla Football Academy ti o wa ni Karshi ni Federal Capital Territory .
Ìgbésíayé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Sani Lulu ni wọn bi ni Zaria, ni ipinle Kaduna ni ọjọ kẹrindínlógún oṣù kẹrin ọdún 1958. O lọ si Federal Government College Warri, ipinlẹ Delta lati ọdún 1971 sí 1976. Lẹyìn ti o pari IJMB ni ilè ìwé Basic Studies Zaria ni ọdún 1977, o si gbá oyè ni Quantity Surveying lati Fasiti Ahmadu Bello ní Zaria ní ọdún 1980[3]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ https://www.blueprint.ng/sani-lulu-victor-oyofo-where-are-they-now/
- ↑ https://thenationonlineng.net/sanni-lulu-god-ordained-my-impeachment-as-nff-president/
- ↑ Empty citation (help)admin (16 May 2019). "Kogi Guber Race: Alhaji Sani Lulu, A Quintessential Enigma". :: Kogi Reports. Retrieved 1 September 2022.