Sani Ma'aruf Nass
Ìrísí
Sani Ma'aruf Nass jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. O jẹ ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè ẹkùn ìdìbò Minjibir/Ungogo ni ilé igbimọ aṣòfin apapọ. Wọ́n bi ni ọdún 1979, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Kano. Ohùn ni wọ́n dibo yàn ti o rọ́pò Bashir Babale wọ́n dibo yàn gẹgẹbi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà nínú ètò ìdìbò ọdún 2019 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC).[1][2] O daba dofin ní ilé igbimọ aṣòfin wípé láti ṣe itọju àwọn òní jamba ọkọ ni kíákíá.[3] O ṣètò owó ìrànwo fún àwọn ènìyàn ẹkùn ìdìbò rẹ ṣùgbọ́n àwọn ẹgbẹ́ alátakò bu ẹnu àte lù.[4]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-07.
- ↑ Gaddafi, Ibrahim Tanko (2023-01-06). "14 of 27 Kano lawmakers failed to sponsor a bill | NASS Scorecard". OrderPaper (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2025-01-17. Retrieved 2025-01-07.
- ↑ "House of Reps Ask Humanitarian Ministry, NEMA to Assist over 40 Accident Victims at Kwanar Dumawa, Kano". THE LEGISLATURE (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-03-16. Retrieved 2025-01-07.
- ↑ Reporter, Our (2023-02-06). "My empowerment scheme held long before CBN cash swap-Hon Mai Wake". The Nation Newspaper (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-07.