Sani Umar Bala
Ìrísí
Sani Umar Bala jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà ni ilé ìgbìmò aṣòfin àgbà láàrin ọdún 2023 tí di ìsinsìnyí, tinsójú àgbègbè Kunchi/Tsanyawa láti ìpínlè Kano lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC). Won bi ni ọjọ 16 osu kíni ọdún 1970, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Kano State. Wọn dibo yàn sì ilé igbimọ aṣòfinàgbà orílè-èdè Nàìjíríà ni ọdún 2023 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC).[1][2][3]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-07.
- ↑ "10th National Assembly Members - Voter - Validating the Office of the Electorate on Representation". orderpaper.ng. Retrieved 2025-01-07.
- ↑ "National Assembly | Federal Republic of Nigeria". nass.gov.ng. Retrieved 2025-01-07.