Jump to content

Sanni Egidi Abdulraheem

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Sanni Egidi Abdulraheem
Federal Representative
ConstituencyAjaokuta
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbíDecember 29, 1969
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress (APC)
OccupationPolitician

Sanni Egidi Abdulraheem (born 29 December 1969) jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà o jẹ ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà House of Representatives fún ẹkùn idibo Ajaokuta ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà láti ìpínlè Kogi State.[1][2][3]

Ni ọdun 2023, Sanni Abdulraheem, oludij lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC), ni wọn diboyan láti sójú ẹkùn idibo ajaokuta ni ilé igbimọ aṣòfin àgbà láti ìpínlè Kogi.[4]

  1. Jimoh, Yekini (2024-03-18). "Ramadan: Kogi lawmaker, Abdulraheem, distributes food items to constituents". Tribune Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2024-12-22.
  2. "Hon Sanni Egidi Abdulraheem; Combining Legislative Business With Constituency Development in Ajaokuta Federal Constituency". Kogi Reports (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2024-09-03. Retrieved 2024-12-22.
  3. Ogunseyin, Oluyemi (2024-11-02). "Lawmaker empowers constituents with entrepreneurial skills". The Guardian Nigeria News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2024-12-22.
  4. Akinfehinwa, John (2023-02-28). "APC's Abdulraheem wins Reps seat for Ajaokuta Federal Constituency in Kogi". Daily Post Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2024-12-22.