Jump to content

Slavery in Africa

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Slavery in Africa

Nítorí ìparun òwò ẹrú Atlántíkì, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìpínlẹ̀ Áfríkà tí wọ́n gbára lé òwò ẹrú àgbáyé ṣe àtúntò ètò ọrọ̀-ajé wọn sí òwò òdodo tí àwọn ẹrú ń ṣiṣẹ́. [1]

Nínú àwọn àkọsílẹ̀ pàtàkì, wọ́n pín òwo-ẹrú sí ìsòri òwo-ẹrú ìbílẹ̀ àti òwo-ẹrú òkèèrè, bóyá ó jẹ́ bẹ́ẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ̀, wọ́n ṣe òwo-ẹrú jákèjádò àgbáńlá-ayé. [2] Òwo-ẹrú nínú ìtàn ilẹ̀ adúláwọ̀ jẹ́ èyí tí wọ́n ṣe lóríṣiríṣi àwọn ọ̀nà: Debt slavery, kíkó àwọn ènìyàn lẹ́rú nígbà ogun, ìkólẹ́rú ológun, ìkólẹ́rú fún iṣẹ́ aṣẹ́wó àti kíkó àwọn ọ̀daràn lẹ́rú ni wọ́n ṣe ni onírúurú àwọn orílẹ̀ èdè adúláwọ̀.[3] Òwo-ẹrú fún iṣẹ́ ilé àti kọ́ọ̀tù tàn kálẹ̀ jákèjádò ilẹ̀ adúláwọ̀. Òwò-ẹrú fún iṣẹ́ ọ̀gbìn náà wáyé, ní apá ìlà Òòrùn adúláwọ̀ àti àwọn apá ìwọ̀ oòrùn adúláwọ̀. Pàtàkì òwò ẹrú òníṣẹ́ ọ̀gbìn gbilẹ̀ si ni sẹ́ntúrì kọkàndínlógún. Owo oru ni Afrika si tun gbile ni awon agbegbe mi ran botile je wipe ko to labe o fin.


Ninu awon iwe litireso ti o ye ju lo. Owo eru ni Afrika pin si eru abinini ati eru tita, gege bi eni pe won ta won koja agbegbe Afrika tabi rara.

  1. "Slavery in Africa, 1804-1936". The Cambridge World History of Slavery. 4. New York: Cambridge University Press. 2017. doi:10.1017/9781139046176. ISBN 9781139046176. https://www.cambridge.org/core/books/the-cambridge-world-history-of-slavery/DDBD4D7ECCB2B8A2C5D97E3609511366.
  2. Dirk Bezemer, Jutta Bolt, Robert Lensink, "Slavery, Statehood and Economic Development in Sub-Saharan Africa", AFRICAN ECONOMIC HISTORY WORKING PAPER SERIES, No. 6/2012, p. 6
  3. Foner, Eric (2012). Give Me Liberty: An American History. New York: W. W. Norton & Company. p. 18.