Jump to content

Solomon Bonu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Solomon Saanu Bonu (a bí i ní ọjọ́ kẹrìndílógún, oṣù kẹfà, ọdún 1972 (16 June 1972) ó jẹ́ olóṣèlú orílẹ́-èdè Nàìjíríà àti ọmọ ilé-ìgbìmọ̀ aṣojúsòfin ti Ìpínlẹ̀ Èkó tó ń ṣojú agbègbè ẹkùn ìdìbò kìn-ní-ín ti Badagry. Ó ti fi ìgbà kan jẹ́ olùbádámọ̀ràn pàtàkì sí gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó lórí ọ̀rọ̀ tó bá jọ mọ́ ètò ìrìnàjò ìgbafẹ́, àṣà, àti ìṣe.[1][2]

Nínú oṣù kẹjọ nínú ọdún 2019, wọ́n yan Bonu gẹ́gẹ́ bí olùbádámọ̀ràn pàtàkì sí gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó lórí ọ̀rọ̀ tó bá jọ mọ́ ètò ìrìnàjò ìgbafẹ́, àṣà, àti ìṣe tí wọ́n sì búra fún un bákan náà. Ó kọ̀wé fi ipò náà sílẹ̀ nínú oṣù karùn-ún ní ọdún 2022 láti lè díje dupò nínú ètò ìdìbò gbogbogboo tí orílẹ́-èdè Nàìjíríà ti ọdún 2023.[3][4] Ní ọjọ́ kọkàndínlógún,oṣù kẹta,ọdún 2023, Bonu padà gẹ́gẹ́ bíi ẹni tí ó jáwé olúborí nínú ètò ìdìbò ẹni tí yóò lọ ṣojú ẹkùn ìdìbò kìn-ní-ín Badagry ní ilé ìgbìmọ̀ aṣojúsòfin ti ìpínlẹ̀ Èkó.[5][6]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "APC House Of Assembly Primaries: Badagry Youths Accuse Sanwo-Olu Of Imposing Candidates On Lagos Constituencies | Sahara Reporters". saharareporters.com. Retrieved 2023-05-14.
  2. Report, Agency (2022-06-03). "Lagos Assembly: Student body rallies support for APC candidate in Badagry". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-05-14.
  3. "TOURISM MINISTRY PLEDGES SUPPORT TO NEW SPECIAL ADVISER". Tourism, Arts & Culture - Lagos State Government (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-05-14.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  4. Abolaji, Adebayo (2022-04-26). "2023: Fayinka, Oyerinde, others to resign from Sanwo-Olu's cabinet this week". Echonews Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-05-14.
  5. Report, Agency (2023-03-19). "Lagos2023: APC wins Badagry State Constituency 1 seat". Premium Times Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-05-14.
  6. Rasaki, Raji. "APC wins Badagry Constituency 1 & 2". PM News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-05-14.