Stella Din-Jacb
Stella Din-Jacob jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn olórí ètò akọ̀ròyìn, agbẹjọ́rò àti adarí ìròyìn àti Olóòtù iléeṣẹ́ ròyìn ní TVC Communications.
Ayé rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Din-Jacob jẹ́ ọmọ bíbí inú Ọ̀gágun Joseph Din àti Christy Din.[1][2] Ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ Plateau State àti pé ọjọ́ ìbí rẹ̀ jẹ́ oṣù Béélú ọjọ́ kankànlá.[3] Ó ṣe kọ́ọ̀sì ìpìlẹ̀ kan nínú ìmọ̀ òfin ní University of Warwick, ó gba B.L rẹ̀ ní Nigerian Law School àti oyè ìmọ̀ òfin ní Yunifásítì Kent, England.[4]
Ó jé adarí ìròyìn ní TVC oníròyìn ní oṣù Ọwàwà ọdún ẹgbẹ̀rùn méjì ólé méjìdínlógún [5] Din-Jacob tún ṣisẹ́ ní ọ̀pọ̀ àjọ ìgbohùn sáfẹ́fẹ́ ti Nàìjìríà pẹ̀lú ìròyìn mẹ́rìnlélógún, Channels Television àti Silverbird Television (Àgbáyé).[3] Nígbàtí ó n ṣiṣẹ́ ní Channels Television láàrín ọdún 1994 and 2002, ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí olùgbéjáde àwọn ètò lórí àtẹ àgbáyé àti ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú agbéròyìn jádé àti olóòtùú .[4] Ó tún ṣiṣẹ́ fún ẹ̀rọ ayélujára CNN àti Al Jazeera.[3]
Ní ọdún ẹgbẹ̀rún méjí ólé ogún, àwọn obìnrin ti ètò ak ọ̀royìn Afrika (WIJAFRICA) fi orúkọ Din-Jacob sí ara àwọn mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n tó lágbara jùlọ ní ètò akọ̀ròyìn ní Nàìjíríà.[6]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Monye, Emeka (October 31, 2021). "Breaking: TVC's Director Of News, Stella Din-Jacob Loses Father". lagoscityreporters.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on December 2, 2021. Retrieved December 3, 2021.
- ↑ "Governor Uzodimma mourns Captain Din, condoles family -". TVC News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-11-03. Retrieved 2021-12-02.
- 1 2 3 "JACOB, Din Stella". Biographical Legacy and Research Foundation (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-07-01. Retrieved 2021-12-02.
- 1 2 "TVC Management Team -" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). TVC Communications. Retrieved 2021-12-02.
- ↑ "TVC Communications appoints Stella Din-Jacob as director of news" (Press release) (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). The Guardian (Nigeria). 2018-10-31. Retrieved 2021-12-02.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
- ↑ Olabimtan, Bolanle (October 2, 2021). "Ijeoma Nwogwugwu, Stella Din, Kadaria Ahmed named among 25 most powerful Nigerian female journalists". TheCable. Retrieved December 3, 2021.