Jump to content

Sunday Oladimeji

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Sunday Oladimeji je olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Naijiria . Ó sìn gẹ́gẹ́ bí aṣojú to ń ṣojú ẹkùn ìpínlẹ̀ ìjọba àpapọ̀ Ado Ekiti/Irepodun-Ifelodun ní ilé ìgbìmọ̀ asòfin . A bi ni 1963, o wa lati Ipinle Ekiti . Wọ́n yàn án sí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ní ọdún 2015 lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP). [1] [2]