Tóyìn Abraham

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Toyin Abraham
Toyin Abraham at AMVCA 2020
Ọjọ́ìbí5 Oṣù Kẹ̀sán 1980 (1980-09-05) (ọmọ ọdún 43)
Auchi, Edo, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
  • actress
  • filmmaker
  • producer
  • director
Ìgbà iṣẹ́2003–present
Olólùfẹ́Kolawole Ajeyemi[1][2]

Toyin Abraham[3] tàbí Olutoyin Aimakhu; ni wọ́n bí ní (September 5, 1984). Ó jẹ́ òṣèré orí ìtàgé , olùgbéré-jáde àti adarí eré, ọmọ rílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[4][5][6][7]

Ìbẹ̀rẹ̀ ìgbésí ayé àti ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bi ní ìlú Auchi, tí ó jẹẹ́ ìlú kan ní town in ìpínlẹ̀ Ẹdó ní orílẹ̀-èdẹ Nàìjírìà. Àmọ́ ṣá, ó bẹ̀rẹ̀ ayé rẹ̀ ní ìlú Ìbàdàn, tí ó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìwọ̀ Oòrùn ilẹ̀ Nàìjíríà. Ó gba ìwé ẹ̀rí HND (Higher National Diploma) ní ilé-ẹ̀kọ́ gbogbo-nìṣe ìlú Ìbàdàn ìyẹn (Ibadan Polytechnic), lásìkọ́ yí, ó jẹ́ akẹgbẹ́ pẹ̀lú Dibie, C.B.N aka x7, Tóyìn Abraham ti fara hàn nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ eré, tí ó sì tún ṣẹ̀ṣẹ̀ kópa nínú sinimá àgbéléwò aré tí orúkọ̀ rẹ̀ ń jẹ́ Black Val.

Iṣẹ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Tóyìn bẹ̀rẹ̀ eré orí ìtàgé rẹ̀ nígbà tí gbajú-gbajà òṣèré orí-ìtàgé tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Bukky Wright, wá sí ìlú Ìbàdàn láti yàwòrán eré kan .Ó ti darí, kópa àti gbé eré jáde fúnra rẹ̀, lára rẹ̀ ni Àlání Bàba Làbákẹ́ àti d Èmi ni. Wọ́n yàán gẹ́gẹ́ bí òṣèré amúgbá-lẹ́gbẹ̀ẹ́ obìnrin tó dára jùlọ (Best Supporting Actress) nínú eré orí ìtàgé tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ "Ẹ̀bi mi ni" nínú àmì ẹ̀yẹ 2013 Best of Nollywood Awards , bákan náà ni wọ́n yan Jọkẹ́ Múyìwá fún Best Lead Actress nínú eré tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ Ayítakẹ̀. Ẹ̀wẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn olóṣèlú ló ti pèé láti bá wọn polongo ètò ìdìbò fún Ààrẹ ilẹ̀ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ tí ó jẹ́ adíje dupò sí orí àpèrè Ààrẹ ìyẹn Goodluck Ebele Jonathan ní ọdún 2015. Tóyìn pàá pàà só wípé òun lè kú torí ẹgbẹ́ òṣèlú People Democratic Party (PDP) kú[8] tí ó jẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú tí adíje dupò náà ti ń díje. Àmọ́ ṣá, ó padà yí gbólóhùn rẹ̀ padà wípé òun bẹ àwọn olólùfẹ́ òun wípé kí ẹnikẹ́ni ó má ṣe ta ẹ̀jẹ̀ ẹnikẹni sílẹ̀ lásìkò ìdìbò.

Àwọn eré ìtàgé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Okafor's Law (2016)
  • Love is in the Hair (2016)
  • Àlàní Bàbá Làbákẹ́ (2013)
  • Ẹ̀bi mi ni (2013)
  • Alákadá (2013)
  • Ṣọlá fẹ́ pa mí
  • Ghost and the tout (2018)

Àwọn Fíìmù Rẹ̀ Tí A Yàn[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Alani Baba labake (2013)

Ebi mi ni (2013)

Alakada (2013)

Okafor's Law (2016)

What Makes you Tick (2016)

Love is in the Hair (2016)

Alakada Reloaded (2017)

Esohe (2018)

Hakkunde (2017)

Mentally (2017)

Tatu (2017)

London Fever (2017)

Wives on Strike: The Revolution (2017)

Celebrity Marriage (2017) pẹ̀lú Tonto Dikeh, Felix Ugo Omokhodion , àti Jackie Appiah

The Ghost and the Tout (2018)

Seven and Half Dates (2018)

Disguise (2018)

What just happened (2018)

Elevator Baby (2019)

Don't Get Mad, Get Even (2019)

Made in Heaven (2019)

Two Weeks in Lagos (2019)

The Millions (2019)

Kasanova (2019)

Bling Lagosians (2019)

Nimbe (2019)

Diamonds In The Sky (2019)

Fate of Alakada (2020)

Dear Affy (2020)

Small Chops (2020)

Sola Fe Pami

Shadow Parties (2020)

Kambili (2020)

Fate of Alakada (2020)

Aki and Pawpaw

The Prophetess (2021)

The Therapist (2021)

Day of Destiny (2022)

King of Thieves (2022)

The stranger I know (2022)

The wildflower (2022)

Ẹ tún le wo[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • List of Nigerian film producers

Àwọn ìtọ́ka sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Fans claim Toyin Abraham is expecting another child - NewsWireNGR". NewsWireNGR. May 3, 2022. Retrieved May 29, 2022. 
  2. Adebayo, Segun (January 23, 2022). "My husband not living off my money, he works hard —Toyin Abraham". Tribune Online. Retrieved May 29, 2022. 
  3. "Nollywood Star, Aimakhu Now To Be Called Toyin Abraham". Channels Television. https://www.channelstv.com/2016/12/29/nollywood-star-aimakhu-now-to-be-called-toyin-abraham/. Retrieved 30 December 2016. 
  4. Mix, Pulse (May 27, 2022). "Purit unveils Toyin Abraham as brand ambassador for 30 years anniversary". Pulse Nigeria. Retrieved May 29, 2022. 
  5. Obinna, Chioma (April 15, 2022). "Toyin Abraham soars higher!". Vanguard News. Retrieved May 29, 2022. 
  6. Bada, Gbenga (May 27, 2022). "Toyin Abraham, Odunlade rejoice as Bamidele Onalaja celebrates with widows - The Nation Newspaper". The Nation Newspaper. Retrieved May 29, 2022. 
  7. "Toyin Abraham and Lizzy Anjorin: Wetin cause dia gbas-gbas - BBC News Pidgin". BBC News Pidgin. May 26, 2021. Retrieved May 29, 2022. 
  8. "I am ready to die for PDP-Toyin Aimakhu". Gistmaster. Archived from the original on 2018-07-26. https://web.archive.org/web/20180726071955/http://niyitabiti.net/2015/03/i-am-ready-to-die-for-pdp-toyin-aimakhu/. Retrieved 2018-01-03. 

Àwọn ìjásóde[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Toyin Abraham on IMDb