Temi Harriman
Ìrísí
Temi Harriman''' ( a bí i ní ọjọ́ kinní osù kinní ọdún 1963) jẹ́ agbẹjọ́rò, olóṣèlú ọmọ orílẹ̀-èdè Nàíjíríà, ó sí jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ aṣòfin tó ń sójú ìpínlẹ̀ Warri lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APP. [1]
Ìbẹ̀rẹ̀ ìgbésí ayé àti iṣẹ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ní ilé ìgbìmọ̀ aṣojú sòfin fún ìpínlẹ̀ Warri lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APP láti 1999 sí 2003. Ó sì tọ́jú ìjókòó rẹ̀ fún sáà mìíràn láti ọdún 2003 sí 2007. [2]
Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Admin (2017-02-20). "HARRIMAN, Hon. Temi". Biographical Legacy and Research Foundation (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-03-01.
- ↑ "Public offices held by Temi Harriman in Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-03-01.