Tessy Igomu
Ìrísí
| Tessy Igomu | |
|---|---|
| Iṣẹ́ | Journalist |
| Employer | The Punch |
Tessy Igomu jé oníroyìn omo orílè èdè Nàìjíríà àti olùdarí eka ìwádìí nì ilé ìwé iroyin The Punch [1][2] Ní odún 2022, ó di obìnrin àkoko tó segun àmì eye oníroyìn gíga Júlo ní Ilà- oòrùn Áfíríkà ni ibi àyeye West Africa Media Excellence Conference and Awards (WAMECA).[3][4]
Awon itokasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Ejekwonyilo, Ameh (2023-11-12). "Nigerian wins West African journalist of the year award". Premium Times Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2024-03-13.
- ↑ "PUNCH welcomes new reporters with an intensive three-week training – PUNCH Media Foundation" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2024-03-13.
- ↑ "Nigerian female journalist wins West Africa Journalist of the Year". Media Foundation For West Africa (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-10-23. Retrieved 2024-03-13.
- ↑ Admin. "Tessy Igomu Wins 2022 West Africa Journalist Of The Year At West Africa Media Excellence Conference And Awards (WAMECA)". Retrieved 13 March 2024.